raw_text
stringlengths
2
128k
tunde eso tunde eso tí a bí ní ọjọ́ 16 oṣù august ọdún 1977 jẹ́ akọ̀ròyìn ọmọ orílẹ̀-èdẹ̀ nàìjíríà alásọyé nípa ọ̀rọ̀ àwùjọ àti olóòtú ìwé-ìròyìn findout ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ pdp tó díje dupò gómìnà ipinle osun ní ọdún 2018 eso ni olùdásílẹ̀ ẹgbẹ́ youthocracy ààrẹ fix nigeria group àti òǹkọ̀wé àwọn ìwé african security solution and vision for africa
tam fiofori tam fiofori tí a bí ní ọdún 1942 tí a tún mọ̀ sí “ uncle tam ” jẹ́ ayàwòrán ìtàn ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà ó gbajúgbajà fún àwọn àwo-orin rẹ̀ tí ń sọ ìtàn-àkọọ́lẹ̀ nàìjíríà fiofori tún jẹ́ òṣèré fíìmù òǹkọ̀wé alárìíwísí àti olùdámọ̀ràn lórí media àwọn kókó inú fíìmù rẹ̀ pẹ̀lú àwọn olórin nàìjíríà biodun olaku jd 'okhai ojeikere àti olu amoda ó máa ń lọ ìrìn-àjò lọ́pọ̀lọpọ̀ fiofori ń gbé ní harlem new york ní àwọn ọdún 1960 ó di olùṣàkóso sun ra
ado ahmad gidan dabino ado ahmad gidan dabino jẹ́ òǹkọ̀wé èdè hausa òǹkọ̀wé akéde oníròyìn olùṣe fíìmù olùdarí àti òṣèré fíìmù ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà ó kọ̀wé fún bíi ọgbọ̀n ọdún lórí àwọn àkọ́lé oríṣiríṣi ó ti ṣàgbéjáde àwọn ìwé ìtàn àròsọ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún ó ti gba àmì-ẹ̀yẹ member of the order of the niger mon ní ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹsàn-án ọdún 2014 láti ọwọ́ ààrẹ goodluck ebele jonathan àwọn àmì-ẹ̀yẹ tó gbà èyí ni àtòjọ àwọn àmì-ẹ̀yẹ tí gidan dabino gbà
shaibu husseini shaibu husseini tí a bí ní ọjọ́ 4 oṣù kejìlá ọdún 1970 jẹ́ akọ̀ròyìn ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà tó tún jẹ́ olórin alábòójútó àṣà pr àti agbaninímọ̀ràn lórí ẹ̀rọ ayélujára àti olùtọ́jú fíìmù ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ẹ̀kọ́ mass communication ní university of lagos ó sì ti kàwé ní lagos state university school of communication àti ní university of lagos níbi tí ó ti gba bsc first class ní mass communication àti msc distinction bákan náà wọ́n ṣe àpejúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi “akọ̀wé ìwé-ìpamọ́ tó ṣe déédé jù lọ” lórí àwọn àkọ́lé tí ó jọ mọ́ nollywood ní ọdún 2010 ó ṣàtèjáde ìwé rẹ̀ tí àkọ́lé rẹ̀ ń jẹ́ moviedom tí ó sọ àwọn ìpele ìdàgbàsókè ti nollywood ó jẹ́ olórí ìgbìmọ̀ ti àwọn olùṣàkóso ti ọdún 2017 ní africa movie academy awards
chris ihidero chris ihidero tí a bí ní ọjọ́ kàndínlọ́gún oṣù kẹta ọdún 1976 jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà tó ń gbé fíìmù jáde òun ni olórí òǹkọ̀wé àti olóòtú mnet ìtàn ìgbésí ayé ẹ̀ ihidero kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ẹ̀kọ́ literature-in-english láti yunifásitì ìpínlẹ̀ èkó àti ní yunifásitì ìlú ìbàdàn ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi òṣèré ó rí-ìtàgé akàròyìn oníròyìn àti olóòtú ìwé-ìròyìn àti olùkọ́ ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga láti ọdún 2005 ni ó ti jẹ́ olùkọ́ ní yunifásitì ìpínlẹ̀ èkó
adewale maja-pearce adewale maja-pearce tí a bí ní ọdún 1953 jẹ́ òǹkọ̀wé akọ̀ròyìn àti lámèyítọ́ tó gbajúgbajà fún àwọn àròkọ rẹ̀ ó ti kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìwé bíi my father's country ní ọdún 1987 àti the house my father built ní ọdún 2014 àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìwé onítàn ìbẹ̀ẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ adewale maja-pearce ní a bí ní ilu lọndọnu england sínú ìdílé kan tí wọ́n jẹ́ ọmọ gẹ̀ẹ́sí àti yorùbá ó dàgbà sí ìpínlẹ̀ èkó orílẹ̀-èdè nàìjíríà ó lọ sí ilé-ìwé st gregory ní obalende láti ọdún 1965 wọ 1969 ó sì padà lọ sí ìlú britain láti kẹ́kọ̀ọ́ si ní university college of wales ní ìlú swansea ba 197275 ó sì tún lọ sí school of oriental and african studies tó jẹh london university 1984-86 níbi tí ó ti gboyè masters nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ nípa africa
may ellen mofe-damijo may ellen ezekial mofe-damijo 1956 - 1996 tí a tún mọ̀ sí mee jẹ́ akọ̀ròyìn àti òǹkọ̀wé tó ṣàtẹ̀jáde classique magazine ìwé-ìròyìn náà gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ akọ̀ròyìn bíi dele momodu ben charles obi àti rudolf okonkwo mofe-damijo tún kọ àwọn ìwé díẹ̀ bíi dream maker àti center spread
moky makura moky makura jẹ́ òǹkọ̀wé ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà akọ̀ròyìn òṣèrébìnrin àti oníṣòwòbìnrin tó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi olùdarí africa no filter èyí tó jẹ́ ilé-iṣẹ́ tó ń rí sí àyípadà tó ń bá ilè africa látàri ẹ̀rọ ayélujára ìgbésí ayé wọ́n bí makura ní èkó lórílẹ̀-èdè nàìjíríà gẹ́gẹ́ bí ọmọ ìdílé akisemoyin èyí tó jẹ́ ìdílé oba ní nàìjíríà ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ètò ìṣèlú ètò ọ̀rọ̀-ajé àti ìmọ̀ òfin láti yunifásitì ti buckingham ní ọdún 1998 ó kó lọ sí south africa àti ní ọdún 1999 ó bẹ̀rẹ̀ ilé-iṣẹ́ tirẹ̀ òun ni olùṣàkóso kejì fún communications africa ní bill and melinda gates foundation láti ọdún 2017 ó jẹ́ aṣojú ẹgbẹ́ náà ní south africa
joy ogwu joy uche angela ogwu tí a bí ní ọjọ́ kejìlélógún oṣù kẹjọ ọdún 1946 jẹ́ mínísítà nàìjíríà tẹ́lẹ̀rí àti asojú nàìjíríà sí ẹgbẹ́ united nations ní new york láàrin ọdún 2008 sí 2017 òun ni obìnrin àkọ́kọ́ láti jẹ́ asojú sí egbẹ́ united nations làti orílẹ̀-èdè nàìjíríà kí ó tó di mínísítà ogwu tí ó jẹ́ ọmọ ìpínlẹ̀ dẹ́ltà jẹ́ adarí àgbà nigerian institute of international affairs niia ààrẹ olusegun obasanjo yàn gẹ́gẹ́ bi òkè òkun ní ọjọ́ ọgbọ̀n oṣù kẹjọ ọdún 2006
reubeni muoka reuben muoka jẹ́ olóòtú ìbánisọ̀rọ̀ fún vanguard newspaper nígbà kan rí ó sì tún fìgbà kan jẹ́ olùdarí àgbà fún nigeria first mobile telephone operator lọ́wọ́lọ́wọ́ ó jẹ́ olùdarí public affairs fún nigerian communications commission ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ muoka kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ẹ̀kọ́ iṣẹ́ tíátà ní university of ilorin ó sì tún lọ sí university of lagos láti kẹ́kọ̀ọ́ nípa mass communications níbi tí ó ti fara ṣíṣẹ́ nínú public relations àti advertising ẹgbẹ́ tó dara pọ̀ mọ́ muoka jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ nigerian union of journalist nigeria institute of public relations àti registered practitioners of advertising
otosirieze obi-young otosirieze obi-young tí a bí ní ọdún 1994 jé òǹkọ̀wé ọmọ orílẹ̀-èdè naijiria olóòtú àti akọ̀ròyìn ó jẹ́ olóòtú àgbà fún open country mag èyí tó jẹ́ ìwé-ìròyìn tó sọ nípa ilẹ̀ africa àti àwọ lítíréṣọ̀ rẹ̀ ó jẹ́ olóòtú ti folio nigeria èyí tó jẹ́ apá kan cnn tó ń sọ̀rọ̀ nípa iṣẹ́-ọnà orílẹ̀-èdè naijiria ìdókòwò rẹ̀ àti eré-ìdárayá rẹ̀ ó jẹ́ igbákejì olóòtú ti ìwé-ìròyìn orí ẹ̀rọ-ayélujára brittle paper ní ọdún 2019 ó jáwé olúborí ó sì gba àmì-ẹ̀yẹ the future awards africa fún lítírẹ́ṣọ̀
reuben muoka reuben muoka jẹ́ olóòtú ìbánisọ̀rọ̀ fún vanguard newspaper nígbà kan rí ó sì tún fìgbà kan jẹ́ olùdarí àgbà fún nigeria first mobile telephone operator lọ́wọ́lọ́wọ́ ó jẹ́ olùdarí public affairs fún nigerian communications commission ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ muoka kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ẹ̀kọ́ iṣẹ́ tíátà ní university of ilorin ó sì tún lọ sí university of lagos láti kẹ́kọ̀ọ́ nípa mass communications níbi tí ó ti fara ṣíṣẹ́ nínú public relations àti advertising ẹgbẹ́ tó dara pọ̀ mọ́ muoka jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ nigerian union of journalist nigeria institute of public relations àti registered practitioners of advertising
ogechukwukanma ogwo ogechukwukanmawes ogwo jẹ́ olùgbóhùnsáfẹ́fẹ́ àti olóòtú orí rédíò tó ń ṣiṣẹ́ lọ́wọ́lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bíi olóòtú ètò orí brilla fm lẹ́yìn tó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú raypower fm ó ti ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí olóòtú ètò orí rédíò fún bíi ọdún méjìlá ó bẹlrẹ̀ pẹ̀lú ètò kan tọ́ pẹ̀ ní 'straight from the heart' lórí raypower fm ní oṣù kẹrin lọ́dún un 2002 lẹ́yìn náà ó di olóòtú ètò lórí ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán níbi tí ó ti jẹ́ olóòtú àwọ ètò bíi ‘top 10 countdown show’ àti ‘rock radio’ ní oṣù kẹjọ ọdún 2003 ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ pẹ̀lú brilla 989 fm èyí tó wà ní ìpínlẹ̀ èkó ó ti ṣe olóòtú awọn ètò bíi ‘whistles of the night’ ‘the afternoon blazing drive’ ‘top 8 countdown’ ‘the sunday morning show’ àti ‘the super morning show’ lórí brilla fm ó ti gbàlejò àwọn olókìkí eléré ìdárayá bíi 2face idibia d'banj don jazzy ali baba mike ezuruonye rita dominic olamide kenny d1 omawumi àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ
malcolm ohanwe malcolm ohanwe tí wọ́n bí ní ọdún 1993 ní munich jẹ́ akọroyin ará german-nigerian gbajúgbajà lórí ẹ̀rọ-ayélujára àti olóòtú ètò orí ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán eniyan media ati agbalejo tv ìgbésí ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ malcolm ohanwe tí wọ́n bí ní munich ní germany ìyá rẹ̀ jẹ́ ará palestine nígbà tí bàbá rẹ̀ sì jẹ́ ọmọ naijiria ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi akọ̀ròyìn lẹ́yìn tó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní ilé-ìwé girama gẹ́gẹ́ bí òǹkọ̀wé fún german television network prosieben àti bíi olóòtú ilé-iṣẹ́ german kan tí orúkọ wọn lórí ẹ̀rọ-ayélujára ń jẹ́ rap2souldeó kẹ́kọ̀ọ́ nípa èdẹ̀ gẹ̀ẹ́sì middle eastern studies àti romance studies ní ludwig-maximilians-university ní munich lẹ́yìn náà ó kọ́ èdè arabic german english french italian àti spanish ó sì ń fi ṣe iṣẹ́
chris okolie chris maduabrochukwu okolie tí wọ́n bí ní ọdún 1949 tí ó sì kú ní ọdún 2007 jẹ́ olùpolówó eré orin naijiria àti aṣàtẹ̀jáde ìwé tí ó sì tún jẹ́ olùdásílẹ̀ new breed organization àti aṣàgbéjáde ìwé-ìròyìn new breed ìgbésí ayé rẹ̀ okolie bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi olùpolówó orin ní àwọn ọdún 1960 tó ń ṣègbélárúge àwọ ètò kékèèké ní gbọ̀ngán jk randle àti ymca ní ipinle eko ó kẹ́kọ̀ọ́ nípa ìkéde fúngbà díẹ̀ ní watford college ní london kí ó tó padà sílẹ̀ nàìjíríà
yusuph olaniyonu yusuph adebola olaniyonu jẹ́ akọroyin agbẹjọ́rò àti alábòójútó tó ń ṣiṣẹ́ bíi olùdámọ̀ràn pàtàkí lórí media àti ìpolówó sí ààrẹ ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin ilẹ̀ naijiria bukola saraki ìgbésí ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ yusuph olaniyonu ni wọ́n bí sí ìlú èkó ní ọjọ́ kẹtàlá oṣù keje ọdún 1966 ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní ogun state polytechnic abeokuta èyí tí a mọ̀ sí moshood abiola polytechnic báyìí láàrin ọdún 1983 sí 1988 ó sì jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ tó dára jù lọ láti ẹ̀ka ẹ̀kọ́ mass communication
dapo olorunyomi oyedapo oyekunle dapo olorunyomi tí wọ́n bí ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kọkànlá ọdún 1957 jẹ́ akọ̀ròyìn ọmọ orílẹ̀-èdẹ̀ naijiria òun ní olóòtú àgbà fún ìwé-ìròyìn premiun times èyí tí ń ṣe ìwé-ìròyìn ti ilẹ̀ nàìjíríà òun kan náà ni olùṣàkóso àgbà fún premium times fún investigative journalism ptcij òun ni olùdarí fún economic and financial crimes commissin efcc
kolade dominate olowu victor akolade olowu tí wọ́n bí ní ọjọ́ 8 oṣù october ọdún 1992 jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè naijiria tó ń ṣịṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi agbóhùnsáfẹ́fẹ́ àti oníṣòwò orí ẹ̀rọ ayélujára tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí kolade mr dominate ìgbésí ayé rẹ̀ wọ́n bi ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kẹwàá ọdún 1992 ní ìlú ijebu ipinle ogun ní orílẹ̀-ede naijiria ó lọ sí ilé-ìwé mayflower school ní ikenne fún ilé-ìwé girama rẹ̀ ó sì tè síwájú si láti kẹ́kọ̀ọ́ nínú ìgbé-ìwádìí-jáde ní federal radio corporation of nigeria
dj xclusive rotimi alakija tí á bí ní ọjó kérín-dín-lógún ósù kéwáà ọdún 1980 tí òpò mò sí́ dj xclusive ó jé disc jockey nàjíríà álágbéjádẹ ígbásílè ọrín átì olórìn álágbásílè ìbèrè áyé england ní á tí bí rotimi alakija sí ówó àwón óbí náìjíríà ní òdómódé ó pádá sí náìjíríà látì lépà èkó ní ílé èkó king's college ị̀lú èkó rotimi alakija pádà sí uk látì kó èkó physics átì ìmò sáyénsì kómpútà ní yúnífásítì reading ní bí tí ó tí gbá oyé ékò ílé-ìwè gígá ó tún pádà kó ékò ísúná ówó kómpútà ní ísé dj xclusive bérè ísé ójógbón disc jockey ní ódún 2003 nípà òpò ìsé sísé ní órísí ílé íjó álé pélù penthouse funky buddha átí jalouse láàrín áwón ódún ísé rè dj xclusive tí bá òrísírísí áwón òṣèrè bí àtí sísé pó ní ábálá tí ódún 2010 tí tí ó wáyé ní united states dj xclusive gbá àmì éyé dj tí ó dárájú ní áyé ́ á yán látì díjè dj tí ó dárájù ní átúsè tí ódụ́n 2011 tí ó tún sé fíìhàn ní house party ódún 2013 ní ódún 2011 dj xclusive dí ílé fún 969 ó sí dárápò mó gégébí òsísé dj tí dj xclusive sé ígbéjádè orín kán i'm xclusive tí ólórín tí uk-náìjíríà ígbésí áyé áráéní dj xclusive fé tinuke ogundero ní ódún 2015 ótún jé ábúrò si ólówó náìjíríà
florence seriki florence seriki mfr tí a bí ní ọjọ́ kẹríndínlógún oṣù kẹjọ ọdún 1963 tí ó sì fi ayé sílẹ̀ ní ọjọ́ kẹta oṣù kẹta ọdún 2017 jẹ́ olùdásìlẹ̀ àti adarí ilé-isé omatek ventures plc ilé-isé nàìjíríà àkọ́kọ́ ní áfríkà láti ṣe èrọ kònpútà àti àwọn ẹ̀yà ara kònpútà ìpìlẹ̀ ayé àti ẹ̀kọ́ rẹ̀ wọ́n bí seriki ní ìpínlẹ̀ èkó ṣùgbọ́n bàbá rẹ̀ jẹ́ ọmọ ìpínlẹ̀ delta ó lọ ilé-ìwé sẹ́kọ́ndírì ní reagan memorial baptist secondary school sabo yaba láàrin ọdún 1975 àti 1980 ó sì tẹ ẹ̀kọ́ rẹ̀ síwájú ní federal school of science ẹ̀kọ́ ó gba àmì-ẹ̀yẹ bachelors of science ní yunifásitì ilé-ifètí àwọn ènìyàn wá padà mọ̀ sí yunifásítì ọbáfẹ́mi awólọ́wọ̀ ile-ife
akintunde popoola akintunde popoola jẹ biṣọọbu anglican ni naijiria o jẹ bishop ti diocese offa titi di ọdun 2018 o si jẹ aṣoju ti gusu ibadan bayi
nana asmaʼu nana asmaʾu gbogbo orúkọ rẹ̀ ni asmaʾu bint shehu usman dan fodiyo lárúbáwá ‎ 17931864 jẹ́ ọmọ ọba fula akéwì olùkọ́ àti ọmọ ọ̀lùdásílẹ̀ sokoto caliphate usman dan fodio ó jẹ́ ẹni tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ yẹ́ sí ní apá àríwá nàìjíríà ọ̀pọ̀lọpọ̀ má ń fi ṣe àpèjúwe bí obìnrin ṣe le jẹ́ akọ̀wé tí yó sì wà láàyè ara rẹ̀ ni islam àwọn míràn tún ròó pé ó wà lára àwọn tó kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ jíjà fún ètọ́ ọmọbìnrin ní ilẹ̀ áfríkà
iṣegbefabo
playboi carti jordan terrell cartera bi ní ọjọ́ kẹtàlá oṣù kẹsàn-án ọdún 1996 tí ọ̀pọ̀lopọ̀ mọ̀ sí playboi carti jẹ akọrin ọmọ orílẹ̀-èdè amẹrika lati atlanta georgia
halle akorin halle orúkọ àbísọ rẹ̀ ni halle grace ihmordu a bi ní ọjọ́ kẹtàdínlọ́gún oṣù kejìlá jẹ́ òṣèrébìnrin akọrin àti oníjó ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà tí ó ń ṣiṣẹ́ fún n3rd records iṣẹ́ rẹ̀ ní ọdún 2008 ó ṣeré fún ìgbà àkọ́kọ́ nínú fíìmù relentless 20082009 wọ́n padà ṣe àgbéjáde fíìmù náà ní bfi london film festival ní ọdún 2010 èyí ni fíìmù àkọ́kọ́ tí ó ti ṣeré àwọn òṣèré tí ó tún wà nínú fíìmù náà ni gideon okeke nneka egbuna jimmy jean-louis àti tope oshin ogun kí ó tó di òṣèrébìnrin halle ma ń jó ó ti jó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdíje ìjọ́ ó sì jáwé olúborí ní àwọn ìdíje bi ìdíje channel o dance africa àti the last female standing ní maltina dance hall ọdún 2008 ní ọdún 2012 ó ṣe àgbéjáde orin àkọ́kọ́ rẹ̀ falling in love ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn sì gba ti orin náà
gabriel akinbolarin akinbiyi gabriel akinbolarin akinbiyi a bi ni ojo karun osu kejila odun 1949 o se igbeyawo pelu iyaafin stella a akinbiyi ni nnkan bi odun merinlelogbon seyin ni odun 1956-1961 o lo si ile iwe st john's ti anglican oke igbo leyin na o pada lo si ile iwe local authority modern oke igbo ni ọdun 1962-1964 lẹyin na o lọ si ile-ẹkọ ikẹkọ diocesan wusasa zaria dtc ni ọdun 1975-1976 o jẹ bishop ti akoko ni agbegbe anglican ti ondo ni ijo ti orele ede nàìjíríà titi di ọdun 2019 o pari ni imanuel college ti theology ibadan ni 1978 o jade ni 1981 o jẹ diakoni ni ọdun kanna ati pe o ṣe ehonu ni 1982 o tẹsiwaju ninu iṣẹ ẹkọ rẹ si oak hill college ni ilu awon alawo funfun ni odun 1987-1990 nibiti o ti ṣe ni dhe ba o si lọ si king's college london laarin 1999-1991 nibiti o ti gba oga ni eko nipa esin ó ti sìn ní ọ̀pọ̀ ṣọ́ọ̀ṣì tó wà ní apá àríwá nàìjíríà irú àwọn ibi bẹ́ẹ̀ ni zaria kaduna kano gusau offa àti akoko báyìí
as aventuras de gui estopa as aventuras de gui estopa jẹ jara ti ere idaraya ará brasil tí wọ́n gbé jáde lọ́dún 2009
aso
ìró ati bùbá
monica friday nigerian film actress influencer realtor model and producer monica friday tí a bí ní ọjọ́ ọ̀kàn-dín-lógún oṣù kẹrin ọdún 1988 jẹ́ òṣèré fíìmù ilẹ̀ nàìjíríà oní-ipa realtor model àti olùdarí ètò ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ẹ̀kọ́ rẹ̀ a bí monica ní badagry ó sì dàgbà ní ajégúnlẹ̀ àdúgbò tí ó wà ní ìlú èkó sínú ilé onígbàgbọ́ ó bẹ̀rẹ̀ ẹ̀kọ rẹ̀ ní ilé-ẹ̀kọ́ mistermis kiddies ó parí ilé-ìwé gírámà ní ilé-ìwé gíga newland senior secondary èkó kó tó di pé ó lọ sí yunifásítì olabisi onabanjo ní ìpínlẹ̀ ògùn níbi tó ti kàwé 'mass communication' iṣẹ́ rẹ̀ ó ṣe ìfarahàn tẹlifísàn àkọ́kọ́ rẹ̀ tí ó ṣe ipa bí àfikún nínú iṣẹ́ àkànṣe wale adenuga tí àkọ́lé rẹ̀ ni 'new song' ipa fíìmù àkọ́kọ́ gbòógì rẹ̀ jẹ́ ní ọdún 2015 nígbà tí ó farahàn ní fíìmù remi vaughan-richards 'unspoken' monica ti ṣe ìfarahàn ní járá m-net tí ó gùn-gùn ọdún 2015 “do good” àti fíìmù tale africa “dérè” tí a tú sílẹ̀ ní ọdún 2016 ní ọdún 2019 ó farahàn nínú fíìmù “zena” bí rexiha
joshua olufemi joshua olufemi tí wọ́n bí ní ọjọ́ 22 oṣù keje ọdún 1983 jẹ́ oṣìṣẹ́ orí ẹ̀rọ-ayélujára ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà àti olùdásílẹ̀ ìmọ̀-ẹ̀rọ fún àwọn ará ìlú òun ni olùdásílẹ̀ dataphyte òun sì ni olùdarí ètò premiun times cntre for investigative journalism èyí tí wọ́n ń pè báyìí ní the centre for journalism innovation and development - cjid olufemi ni akọròyìn tó tún jẹ́ aṣojú premium times ní international consortium of investigative journalists icij fún ilé-iṣẹ́ atẹ̀wéjáde panama papers àti paradise papers ètò ẹ̀kọ́ àti iṣẹ́ olufemi kẹ́kọ̀ọ́ gboyè bachelor's degree nínú ẹ̀kọ́ economics láti ilé ìwé gíga olabisi onabanjo ní ọdún 2005 àti oyè master's degree nínú ẹ̀kọ́ measurement and evaluation láti ilé-ìwé gíga university of lagos ní ọdún 2013 kó tó lọ sí said business school ti university of oxford níbi tí ó ti gba oyè nínú ẹ̀kọ́ global financial technology o jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ institute of chartered economists of nigeria
sam oritsetimeyin omatseye sam omatseye jẹ́ akéwì òǹkọ̀wé ìtàn àròsọ akọ̀tàn fún eré oeí-ìtàgé àti akọ̀ròyìn ọmọ orílẹ̀-èdè naijiria wọ́n bí sam ní ọjọ́ 15 oṣù june ọdún 1961 ipinle delta nigeria ni ó sì ti wá ó gba àmì-ẹ̀yẹ ti ọdún 2019 fún national productivity order of merit npom ètò ẹ̀kọ́ sam omatseye lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ girama ti government college ughelli ìpínlẹ̀ bendel tẹ́lẹ̀ ipinle delta láti ọdún 1973 sí 1979 fún ètò ẹ̀kọ́ girama rẹ̀ ó sì gba ìwé-ẹ̀rí ilé-ìwé west african school ó lọ sí federal school of arts and science victoria island lagos fún ètò ẹ̀kọ́ gíga rẹ̀ ó kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìmọ̀ history ní university of ife tó ti di obafemi awolowo university láti ọdún 1980 sí 1985 ó sì gba bachelor of arts degree iṣẹ́ rẹ̀ ó kọ́ èdè gẹ̀ẹ́sì àti lítíréṣọ̀ ní aminu kano commercial college kano nígbà tó ń ṣe nysc láti ọdún 1985 sí 1986 láti ọdún 1987 sí 1988 ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi ajábọ̀-olùṣèwádìí ní newswatch magazine ó sì ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ nínú ọ̀rọ̀ ilẹ̀ ajèjì àti àṣà ní ọdún 1988 ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí òǹkọ̀wé fún african concord magazine ó sì ṣagbátẹrù oríṣiríṣi ìtàn tó ṣe àkọsílẹ̀ ìtàn ibrahim babangida ó di igbákejì olóòtú òṣèlú ti àwọn ìwé-ìròyìn concord ní ọdún 1989 àwọn ìwé rẹ̀ ìwé kehkeré awọn aramada àwọn ewì àwọn eré tó kópa nínú
sa'a ibrahim sa'a ibrahim jẹ́ akọ̀ròyìn ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà àti òṣìṣẹ́ ètò ìbáraẹnisọ̀rọ̀ òun ni obìnrin àkọ́kọ́ tó máa di alága broadcasting organisation of nigeria bon òun sì ni olùdarí àgbà fún ẹ̀rọ̀-amóhùn máwòrán ti abubakar rimi ìgbésí ayé rẹ̀ hajia sa'a ibrahim ni wọ́n bí sínú ìdílé malam ibrahim àti yalwa bello ní ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kẹrin ọdún 1960 ní magashi quarters ní ìjọba ìbílẹ̀ gwale ní ipinle kano
nneka àkọrin nneka lucia egbuna tí a bí ní ọjọ́ kẹríndínlógún oṣù kejìlá ọdún 1980 jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà akọrin àti òṣèré bìnrin ó ma ń kọrin ní èdè gẹ̀ẹ́sì igbo àti èdè pidgin nàìjíríà ìpìlẹ̀ rẹ̀ a bí nneka lucia egbuna ní warri ìpínlẹ̀ dẹ́ltà nàìjíríà a sì tọ dàgbà ní ìlú kan náà ìyá rẹ̀ jẹ́ ọmọ orílẹ̀ ède jẹ́mánì bàbá rẹ̀ sì jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà òun ni àbíkẹ́yìn nínú ọmọ mẹ́rin nígbà tí nneka jẹ́ ọmọ ọdún méjì ìyá rẹ̀ fi bàbá rẹ̀ sílè nígbà tí bàbá rẹ̀ fẹ́ ìyàwó míràn ìyàwó tuntun yìí fi ìyà jẹ àwọn ọmọ ìyàwó àkọ́kọ́ pàápàá jùlọ àwọn ọmọ méjì tí ó jẹ́ àbíkẹ́yìn—nneka àti ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin anato
gbenga omotoso gbenga omotoso tí wọ́n bí ní ọjọ́ 11 oṣù november ọdún 1961 jẹ́ akọ̀ròyìn àti òǹkọ̀wé òun ni olóòtú ìwé-ilròyìn the nation títí tí wọ́n fi yàn án sípò commissioner tó ní ṣe pèlú lagos state ministry of information and strategy gómínà ìpínlẹ̀ èkó ìyẹn babajide sanwo-olu mu ṣèbúra láti wọ iṣẹ́ ní ọdún 2019 ìgbésí ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ ọjọ́ kọkànlá oṣù kọkànlá ọdún 1961 ni wọ́n bí omotoso ó wá láti ipinle osun tó wà ní apá gúúsù mọ́ ìwọ-oòrùn ilẹ̀ nàìjíríà ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ba nínú ìmọ̀ èdè gẹ̀ẹ́sì àti lítíréṣọ̀ ní university of benin nigeria ní ọdún 1984 ó tẹ̀síwájú láti gboyè masters nínú ẹ̀kọ́ public and international affairs ní university of lagos akoka tí ó parí ní ọdún 2007 iṣẹ́ rẹ̀ omotoso ti lo ọdún márùndínlógójì nínù iṣẹ́ ìròyìn ó bẹ̀rẹ̀ gẹ́gé bíi akẹ́kọ̀ọ́ tó ń kọ́ nípa iṣẹ́ olóòtú ní ilẹ́-iṣẹ́ ìwé-ìròyìn the guardian ó padà di igbákejì olóòtú ti guardian express níbi tí ó ti di olóòtú saturday guardian ní ọdún 1999 ní ìbẹ̀ẹ̀rè ìwé-ìròyìn comet wọ́n yàn án sípò aṣáájú-ọ̀nà olóòtú ìwé ìròyìn ní ọdún 2006 ó tún di olóòtú aṣáájú-ọ̀nà ti ìwé-ìròyìn the nation ó ti ṣètọ́jú ìwé kan àkọsílẹ̀ olóòtú ní the nation níbi ti ó ti kọ̀wé lórí àwọn ọ̀ràn inú ìlú látàri lílo ọ̀nà àwàdà láti fi ṣàfihàn àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ náà ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ nigeria guild of editors nge àti nigeria union of journalist nuj ó jẹ́ olùfẹ́ eré-ìdárayá lọ́pọ̀lọpọ̀ pàápàá jù lọ bọ́ọ̀lù àfọwọ́gbá ó ti ní láti fi ẹ̀bùn rẹ̀ hàn níbi ìṣàfihàn kan tó ti bá bọ́ọ̀lù náà pẹ̀lú akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ agbábọ́ọ̀lù tó wà ní ipò ogún lágbàáyé tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ aruna quadri tí ó sì ṣe dáadáa àtòjọ àmì-ẹ̀yẹ rẹ̀ omotoso ti gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ àmì-ẹ̀yẹ fún iṣẹ́ títayọ rẹ̀ nínú iṣẹ́ ìròyìn díẹ̀ nínú àwọn àmì-ẹ̀yẹ náà ni àmì-ẹ̀yẹ ti dame ní ọdún 2010 àmì-ẹ̀yẹ ti nigeria media fún olóòtú tó dára jù lọ ní ọdún 2013 àmì-ẹ̀yẹ nigeria media merit fún olóòtú tó dára jù lọ ní ọdún 2015 àti àmì-ẹ̀yẹ nigeria media merit fún olóòtú tó dára jù lọ ní ọdún 2017
chido onumah chido onumah tí wọ́n bí ní ọjọ́ 10 oṣù april ọdún 1966 jẹ́ akọ̀ròyìn òǹkọ̀wé àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn ó ti ṣiṣẹ́ fún bíi ogún ọdún gẹ́gẹ́ bíi akọ̀ròyìn òǹkọ̀wé ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọnìyàn àti oníṣẹ́ ìròyìn ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ghana canada india orílẹ̀ èdè america caribbean àti europe ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè phd nínú ẹ̀kọ́ communication and journalism láti autonomous university of barcelona ní uab orílẹ̀-èdẹ̀ spain ilé-iṣẹ́ tó ń rí sí ètò ààbò ní orílẹ̀-èdẹ̀ naijiria ni ó mu tí wọ́ sì tí í mọ́lé nígbà tí ó wà ní páápá ọkọ̀ òfurufú ti abuja bí ó ṣe ń ti spain bọ̀ nítorí ó wọ ẹ̀wù tí wọ́n kọ we are all biafrans sí ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀ onumah kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní university of calabar tó wà ní ipinle cross river ní orílẹ̀-èdè naijiria ó sì gba ma nínú ẹ̀kọ́ iṣẹ́ ìròyìn láti university of western ontario ní london ontario canada ó tún gba phd kan nínú ẹ̀kọ́ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ àti iṣẹ́ ìròyìn láti autonomous university of barcelona uab spain iṣẹ́ rẹ̀ onumah ṣiṣẹ́ ó sì kọ̀wé fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé-iṣẹ́ ìròyìn ní orílẹ̀-èdẹ̀ nàìjíríà bíi ìwé-ìròyìn sentinel guardian am news pm news the news/tempo concord punch àti thisday newspaper kí oh tó lọ sí accra ní orílẹ̀-èdè ghana ní ọdún 1996 ó sìn gẹ́gẹ́ bíi olùṣàtúnṣe alábàáṣiṣẹ́pọ̀ ti ìwé-ìròyìn insight olùrànlọ́wọ́ olùṣàtúnṣe ìwé-ìròyìn third world network african agenda olùṣekòkáárí west african human rights committee àti correspondent fún ìwé-ìròyìn african observer new york àti africanews service nairobi kenya ìwé àtẹ̀jáde onumah jẹ́ òǹkọ̀wé ó sì ti kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìwé bíi o ti satunkọ awọn iwe lori orisirisi wonyen pẹlu
kate henshaw
tobore ovuorie tobore ovuorie jẹ́ akọròyìn olóòtú ọ̀rọ̀ ìlera àti olùṣèwádìí àgbà pẹ̀lú premium times ìgbésí ayé ovuorie ṣe àtẹ̀jáde ìwé àkọ́kọ́ rẹ̀ ní ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún ó bẹ̀rẹ̀ ìwádìí abélé kan tí àkọlé rẹ̀ jẹ́ inside nigeria's ruthless human trafficking mafia ní ọdún 2013 èyí tí premium times gbé jáde ní ọdún 2014 ovuorie bèrẹ̀ 5000000 èyí tó ń lọ bíi n225million láti ọwọ́ ilé-iṣẹ́ ebonylife fún ìtẹ̀jáde fíìmù kan tí àkọ́lé rẹ̀ ń jẹ́ oloture láìgbé oríyìn fún un ó sọ pé fíìmù náà jẹ́ àfihàn ìrírí rẹ̀ nínú inside nigeria's ruthless human trafficking mafia ẹni tó ni ilé-iṣẹ́ náà ìyẹn mo abudu sọ pé iṣẹ́ ìtàn àròsọ ni fíìmù náà àti pé oríṣiríṣi ìṣẹ̀lẹ̀ òtítọ́ ló mu lóríyá àlàyé náà tún ní àfikún pé fìímu oloture náà wáyé látàrí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú ọ̀pọ̀ àwọn ilé-iṣẹ́ pẹ̀lú àkọsílẹ̀ orísiríṣi lórí gbígbé ènìyàn káàkiri àti ìbálòpọ̀ àfipámúni àwọn àmì-ẹ̀yẹ rẹ̀ ọmọbìnrin náà ti gba àmì-ẹ̀yẹ deutsche welle dw ti ọduhn 2021 èyí tó jẹ́ freedom of speech award
aisha salaudeen aisha salaudeen tí wọ́n bí ní ọjọ́ kẹríndínlógbọ̀n oṣù september ọdún 1994 jẹ́ gbajúgbajà akọ̀ròyìn ajàfún ẹ̀tọ́ obìnrin aṣàgbéjáde ìròyìn àti òǹkọ̀wé tó ń ṣiṣẹ́ ní cnn lọ́wọ́lọ́wọ́ ní oṣù kọkànlá ọdún 2020 ó gba àmì-ẹ̀yẹ future awards africa prize fún iṣẹ́ rẹ̀ nínú ìjábọ̀ ìròyìn àti bí ó ṣe máa ń kọ ìtàn nípa ilẹ̀ afrika wọ́n pè é láti sọ̀rọ̀ ní ake arts and book festival ní dún 2020
ijo kristiẹni ti a rà pada redeemed christian church of god rccg jẹ́ ìjọ pẹ́ńtíkọ́sítì ńlá kan ní ìpínlẹ̀ èkó ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà enoch adébóyè ti jẹ́ alábòójútó ìjọ náà láti ọdún 1981 ìjọ náà tó wà ní èkó ní àwọn olùjọ́sìn tó ń lọ bíi 50000 ní ọdún 2022 ìtàn rev josiah olufemi akindayomi tí wọ́n bí ní ọdún 1909 tó sì kú ní ọdún 1980 dá ìjọ rccg sílẹ̀ ní ọdún 1952 reverend akindayomi yan enoch adébóyè gẹ́gẹ́ bíi alábòójútó ìjọ náà adeboye jẹ́ olùkọ́ ẹ̀kọ́ mathematics ní university of lagos ó sì dara pọ̀ mọ́ ìjọ ní ọdún 1973 wọ́n kọ́kọ́ gba adeboye gẹ́gẹ́ bíi ògbufọ̀ láti máa tú àwọn ìwásù akindayomi láti èdè gẹ̀ẹ́sì sí èdè yoruba wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bíi olùṣọ́-àgùntàn láti mójútó ìjọ náà ní ọdún 1975 yíyàn tí wọ́n yàn án sípò yìí tẹ̀lé ìfilehlẹ̀ tí akindayomi fi lélẹ̀ ní ọdún 1990 ilé-ìwé fún ẹ̀kọ́ bíbélì fún ìjọ redeemed christian church of god jẹ́ dídá sílẹ̀
redeemed christian church of god redeemed christian church of god rccg jẹ́ ìjọ pẹ́ńtíkọ́sítì ńlá kan ní ìpínlẹ̀ èkó ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà enoch adébóyè ti jẹ́ alábòójútó ìjọ náà láti ọdún 1981 ìjọ náà tó wà ní èkó ní àwọn olùjọ́sìn tó ń lọ bíi 50000 ní ọdún 2022 ìtàn rev josiah olufemi akindayomi tí wọ́n bí ní ọdún 1909 tó sì kú ní ọdún 1980 dá ìjọ rccg sílẹ̀ ní ọdún 1952 reverend akindayomi yan enoch adébóyè gẹ́gẹ́ bíi alábòójútó ìjọ náà adeboye jẹ́ olùkọ́ ẹ̀kọ́ mathematics ní university of lagos ó sì dara pọ̀ mọ́ ìjọ ní ọdún 1973 wọ́n kọ́kọ́ gba adeboye gẹ́gẹ́ bíi ògbufọ̀ láti máa tú àwọn ìwásù akindayomi láti èdè gẹ̀ẹ́sì sí èdè yoruba wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bíi olùṣọ́-àgùntàn láti mójútó ìjọ náà ní ọdún 1975 yíyàn tí wọ́n yàn án sípò yìí tẹ̀lé ìfilehlẹ̀ tí akindayomi fi lélẹ̀ ní ọdún 1990 ilé-ìwé fún ẹ̀kọ́ bíbélì fún ìjọ redeemed christian church of god jẹ́ dídá sílẹ̀ awon iwaasu akindayomi lati ede yoruba si geesi o jẹ oluso-aguntan ti ile ijọsin ni ọdun 1975 ìyàn rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí aṣáájú alábòójútó gbogbogbòò ti ṣọ́ọ̀ṣì jẹ́ ìtòlẹ́sẹẹsẹ nípa kíka ìkéde tí akindayomi ti di èdìdì lẹ́yìn ikú ni ọdun 1990 ile-iwe bibeli ti onigbarapada ti ọlọrun jẹ idasile
uzor osimkpa nigerian actress uzoma okwuchi osimkpa jẹ́ òṣèré obìnrin ti ile nàìjíríà tí a mọ̀ sí uzor osimkpa ó jáde ní ipò kárùn-ún ní àkókò kẹsàn-án nínú gulder ultimate search ti ọdún 2012 ìgbésí ayé ó gba òye nínú ètò ọrọ̀ ajé economics education láti yunifásítì ìpínlẹ̀ ábíá ní ilẹ̀ nàìjíríà iṣẹ́ rẹ̀ iṣẹ́ ìṣèré uzor bẹ̀rẹ̀ ní ọdún 2004 nígbà tí ó ṣe ìfihàn nínú fíìmù 'shallow waters' ní ọdún 2005 ó farahàn nínú járá àgbéyẹ̀wò 'wetin dey' ti bbc world service trust àwọn járá tẹlifísàn 'do good' àti hustle jẹ́ kí ó jẹ́ olókìkí díẹ̀ síi lẹ́hìn náà ó ti ṣe ìfihàn nínú àwọn fíìmù àti járá tẹlifísàn èyí tí ó pẹ̀lú tinsel the maze flatmate edge of paradise doctors quarters láàrín àwọn mìíràn uzor osimkpa díje ó sì jáde ní ipò kárùn-ún ní gulder ultimate search ní ọdún 2012 pàápàá bótilẹ̀jẹ́pé ó yọ kúrò lẹ́hìn tí ó ṣòdì sí òfin kan nípa yíyọ kùkùté ìtìjú kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ̀ bí ìjìyà fún ìparí ìkẹhìn ní ìpeníjà ìkẹhìn tí àkọ́lé 'wave your flag' ìyìn ní ọdún 2017 uzor ni a yàn fún ẹ̀ka àwọn fíìmù city people - òṣèré tí ńbọ̀ tí ó dára jùlọ nínú fíìmù gẹ̀ẹ́sì kan uzor osimkpa jáde ní ìkarùn-ún ní wíwá gulder ultimate ní ọdún 2012 àkókò yìí wáyé ní usaka obot akara ìpínlẹ̀ akwa ibom
najite dede najite dede jẹ́ òṣèrébìnrin àti adarí fíìmù ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ó jẹ́ arábìnrin michelle dede àti richard mofe damijo àwọn mẹ́tẹ̀ta jẹ́ òṣèré ìdílé rẹ̀ orúkọ bàbá najite ni ogbeni brownson dede aṣojú nàìjíríà tẹ́lẹ̀rí sí orílẹ̀-èdè ethiopia
hanshin tigers 甲子園 5066521146jpg tigers jẹ ẹgbẹ bọọlu afẹsẹgba japanese kan akopọ awọn tigers hanshin jẹ ẹgbẹ bọọlu afẹsẹgba olokiki julọ ti japan ati pe wọn ni atẹle nla kanti o ba ṣẹgun yoo mu ariwo kan wa si japan oludari ni eyan kan ti oruko re n je shofu okada ni alakoso ati pe o gbajumo ju awon agbabooluawọn alaye ere-ifiweranṣẹ jẹ pataki ti ẹgbẹ yii
angel unigwe nigerian actress born 2009 angel unigwe orúkọ àbísọ rẹ̀ ni angel onyinyechi unigwe tí a bí ní ọjọ́ kẹta-dín-lọ́gbọ̀n oṣù kẹfà ọdún 2005 jẹ́ òṣèré obìnrin ti ilẹ̀ nàìjíríà ó jẹ́ aláfiwé àti aṣètò tí ó tún ṣe ìfihàn nínú àwọn ìkéde tẹlifísàn olókìkí iṣẹ́ rẹ̀ ṣàfimọ̀ sí ilé-iṣẹ́ fíìmù nípasẹ̀ ìyá rẹ̀ unigwe bẹ̀rẹ̀ bí òṣèré ọmọdé tí ó ṣe àfihàn àkọ́kọ́ rẹ̀ ní ọdún 2015 lẹ́hìn tí ó gba àwọn ipa ní 'alison's stand' járá tẹlifísàn nàìjíríà olókìkí àti pé láti ìgbà náà ó ti tẹ̀síwájú láti mú ọkàn àwọn òǹwòrán fíìmù dùn' akòròyìn unigwe ni oníròyìn nàìjíríà obaji akpet àwọn yíyàn rẹ̀ àti àmì ẹ̀yẹ unigwe ti gbádùn ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn yíyàn àti pé ó ti gba àwọn àmì ẹ̀yẹ lọ́pọ̀lọpọ̀ pẹ̀lú òṣèré ọmọdé child actor ti ọdún 2019 ní ààmì ẹ̀yẹ intellects giant ó lọlé pẹ̀lú àmì ẹ̀yẹ best young/promising actor ní ọjọ́ kẹta-dín-lọ́gbọ̀n oṣù kẹwàá ọdún 2019 ní ẹdá ọdún 2019 ti africa movie academy awards amaa òṣèré ọmọdé tí ó dára jùlọ nínú fíìmù kan ní àmì ẹ̀yẹ ọdún 2021 'best of nollywood ' bon fún ipa rẹ̀ nínú 'strain'
wendy lawal yewande lawal simpson jẹ́ òṣèrébìnrin ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà àwọn ènìyàn mọ́ tẹ́lẹ̀rí sí yewande lawal adebisi òun ni ó jáwé olúborí nínú ìdíje miss lagos carnival pageant ní ọdún 2012 ìtàn rẹ̀ yetunde ni ọmọ karùn-ún nínú ọmọ mẹ́fà tí àwọn òbí rẹ̀ bí lawal fẹ́ wanri simpson ní ọdún 2018 ó sì pàdánù ìyá rẹ̀ ní ọdún 2020 ẹ̀kọ́ rẹ̀ lawal's ka ẹ̀kọ́ àkọ́bẹ̀rẹ̀ àti sẹ́kọ́ndírì rẹ̀ ní orílẹ̀-èdè nigeria ó sì tún tẹ̀síwájú láti gba àmì-ẹ̀yẹ bachelor's degree rẹ̀ nínú ìmọ̀ creative arts ní yunifásítì ìlú èkó iṣẹ́ rẹ̀ iṣẹ́ lawal nínú ṣíṣe fíìmù bẹ̀rẹ̀ ni ọdún 2009 lẹ́yìn ìgbà tí ó ṣeré nínú fíìmù living in lagos lẹ́yìnhìgbà náà ó ti ṣeré nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ fíìmù bias the men's club jemeji journey to self the room out of sight foreign love
suntrust bank nigeria limited suntrust bank nigeria limited stbnl jẹ́ ilé iṣẹ́ tó ń pèsè ètò ìnáwó ní orílẹ̀ èdè nàìjíríà tí ó gba ìwé àṣẹ lọ́wọ́ banki gbogboogbò ilẹ̀ nàìjíríà ìyẹn central bank of nigeria àti olùṣàkóso ilé-ìfowopámọ́ orílẹ̀-èdè
diamond bank plc diamond bank plc j olùpèsè iṣẹ́ ìnáwó orílẹ̀-èdè nàìjíríà diamond bank gba nípasẹ̀ access bank ní òṣù kejìlá ọdún 2018 ósì kédè láti parí àwọn iṣówó tí àpapọ̀ ní kíkún ní ìdajì àkọ́kọ́ tí ọdún 2019 diamond bank ti dàpọ̀ ní kíkún pèlú access bank láti kọ́ ǹkan tuntun lákokò tí ó tọ́jú orúkọ access bank pèlú ààmì kan tí ó mú ìrísí diamond bank
child prostitution in nigeria child prostitution in nigeria jẹ́ ọ̀nà ìgba fífi àwọn ọmọdé ṣiṣẹ aṣẹ́wó iṣẹ́ aṣẹ́wo ti di iṣẹ́ tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn rí gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọ̀ọ̀jọ́ wọn kódà tọmọdé àti tàgbà ló ní ṣíṣe yíì gẹ́gẹ́ bí ohun to ń fún wọn ní jíjẹ àti mímu àmọ́ èyí kì í ṣe ọ̀nà tó dára yorùbá bọ̀ wọ́n ní ọ̀nà kan ò wọjà tí ó mú èyí túmọ̀ sí wí pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ ló wà tí ènìyàn lè fí wá jíjẹ àtì mímu ìṣe aṣẹ́wo àwọn ọmọdé nílẹ̀ nàìjíríà ní ó jẹ́ wá lógún ní iṣẹ́ yìí iṣẹ́ aṣẹ́wo iṣẹ́ yìí ní bíba jẹ́ndà kejì ní àṣepọ̀ tí ó lè jẹ́ mímọ̀ọ́mọ̀ fún ara rẹ̀ tàbí wí pé wọn lọ ẹ̀tàn àti ipá fún un làti lè bá ẹlòmíràn ní àṣepọ̀ tí a bá sọ mímọ̀ọ́mọ̀ ọmọdé náà a ma sọ wí pé ó ń ṣiṣẹ́ yìí fún owó ni ṣùgbọ́n tí a bá sọ ti ẹ̀tàn àti ipá èyí lè túmọ̀ sí wí pé ọmọ tí wọ́n mú lọ sókè òkun àìtọ́ ni ìtàn ní ọdún 2019 àjọ tí ń gbógun tí kíkó àwọn ènìyàn lọ sókè òkun lọ́nà àìtọ́ sọ fún cnn wí pé ó tó ọ̀kẹ́20000 obìnrin tí wọ́n tí fì ẹ̀tan àbí ipá mú lọ sí orílé-èdè mali àwọn àjọ yìí sọ fún cnn wí pé àwon ní ẹ̀rí tó dájú lórí ọ̀rọ̀ yii gẹ́gẹ́ bí ìtàn tí àwọn àjọ̀ tó ń gbógun tí ìwà ìbàjé ṣe sọ nípa ti wọn má mú àwọn obìnrin náà ní nigeria wọ́n sọ wí pé ìlú malaysia ni àwọn tí má ṣíṣe pẹ̀lú owó tọ pọ̀ ṣùgbọ́n awọn ò mọ bí àwọn ṣe bá ara àwọn ni málì ní málì yẹn ní àwọn ọdaran yii ti ta ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn obìnrin yíì àwọn yòókù tí wọn ní kó ṣíṣe ní ilé ìtura ní mali náà di títa lati mọ̀ wí pé wọ́n tí tá àwọn fún ilé ìtura náà ohun tó yẹ ka ṣe àkíyèsí rẹ̀ nínú wo pé obìnrin ló sáábà máa ń jẹ́ awon àwọn ohun tó ń fa èyí ohun tó má dá sílẹ̀ àti ọ̀nà àbáyọ la ma mẹ́nubà nínu iṣẹ́ yìí àwọn okùnfà rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe mọ̀ wí pé kò sí nǹkan ni àwùjọ tí kò ní ohun tí ó hún fà á lára àwọn ohun tí ó fa iṣẹ́-aṣẹ́wó ọmọdé ni iṣẹ́ àwọn ọ̀rẹ́ àìnímọ̀ nípa àwọn àrùn tí ó lè fà àdúgbo ẹni àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ iṣẹ́ aṣẹ́wo ní ọ̀nà mímú ọmọdé lọ sókè òkun lọ́nà àìtọ́ ni a ma fẹ́ ẹ̀ mújútó nínu iṣẹ́ yìí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọdé ni ò nímọ̀ nípa àwọn àrùn tí gbóògùn tí wọ́n ma kó tí àwọn bá ń ṣe aṣẹ́wo àti wí pé tí ó bá jẹ́ mímú wọn lọ́nà àìtọ́ lọ sí ibòmíràn ni èyí jẹ́ wí pé ipá lọ ma lò láti fi jẹ́ kí wọ́n ṣiṣẹ́ aṣẹ́wo yìí tí a bá wo ará àdúgbò àti àwọn ọ̀rẹ́ a ma ri wí pé àwọn méjèèjì yìí wà lára àwọn nǹkan tó máa bá ìhùwàsí àwọn ènìyàn lọ rè é kò sí ẹnì kankan tí a lè sọ wí pé àpẹẹrẹ àwọn méjèèjì ò hàn nínu ìhùwàsí rẹ̀ tí ó bá jẹ́ wí pé àwọn ọ̀rẹ́ àwọn ọmọdé yìí bá ń ṣe iṣẹ́ yìí àyè wà wí pé àwọn náà má ṣe é iṣẹ́ àti àìríṣẹ àwọn ọmọdé náà máa ń fà á yorùbá bọ̀ wọ́n ní ọwọ́ tó bá dilẹ̀ ni èṣù ń bẹ̀wò àwọn ohun tí ó máa ń dá sílẹ̀ àrùn kògbóògùn jẹ́ ọ̀kan lára wọn àwọn àrùn bí i hiv/aids àti àwọn àrùn mìíràn tí ó jẹ́ wí pé ènìyàn má á kó látara ìbáṣepọ̀ àwọn àrùn yìí ò kògbóògùn tó túmọ̀ sí wí pé bẹ́ẹ̀ àwọn ọmọdé yìí ṣe ma bá ara wọn láíláí ó tún lè fa ìrònú ọkàn àti ìrẹ̀wẹ̀sí fún àwọn ọmọdé bí àpẹẹrẹ tí ó bá jẹ́ ọmọdé tí wọ́n fi ẹ̀tan àti kíkọpá mú lọ sí ilẹ̀ mìíràn lọ́nà àìtọ́ èyí ma jẹ́ ìrònú ọkàn àti ìrẹ̀wẹ̀sí fun lẹ́yìn tí ó bá rí àwọn ènìyàn gbà á lè kódà ó tún lè fa àbámọ̀ fún wọn lẹ́yìn tí wọn ba ti ko àwọn àrùn tán àwọn ọ̀nà àbáyọ ohun tí a nílò láti ṣe jù ni kí a kó àwọn ọmọdé ní àwọn ewu tó wà ní irú iṣẹ́ yìí ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ní ò mọ àwọn ewu yìí tí a bá kọ́ wọn ní àwọn ewu yìí a ma rí wí pé àwọn ọmọdé púpọ̀ tí ó ń ṣe iṣẹ́ yìí ma dáwọ́ duro lórí rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣe sọ tẹ́lẹ̀ wí pé ọwọ́ tó dá dilẹ̀ ni èṣù bẹ̀wò ó yẹ ka fi àwọn ọmọdé wa tàbí àwọn ọmọdé tí a bá mọ̀ ṣinú iṣẹ́ a ò lè ma dúró de ìjọba ọ̀míràn ni kí a kọ́ àwọn ọmọdé yìí nípa sùúrù yorùbá bọ̀ wọ́n ní sùúrù ni baba ìwà sùúrù yìí nípa iṣẹ́ tì ó jẹ́ àwọn ọmọ ènìyàn ni ohun tí ó yẹ ka à ni wí pé ohun tó kúrò ma padà dùn
ìfọmọdé ṣiṣẹ́ ipá ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà
child abuse in nigeria
action against trafficking in persons and smuggling of migrants in nigeria
national agency for the prohibition of trafficking in persons national agency for the prohibition of trafficking in persons naptip je ajo agbofinro ti ijoba apapo ti nigeriawon daa le ni 2003 lati le koju gbigbe eniyan ati awọn iru iru awọn ẹtọ eda eniyan naptip wa lara awọn ile-ibẹwẹ ti o wa labẹ abojuto ti ile -iṣẹ federal ti awọn ọran omoniyan isakoso ajalu ati idagbasoke awujọ orísun naptip tí a dá silẹ labẹ ìwé-òfin-owo ìjọba-àpapọ̀ kan ní oṣù keje ọjọ 14 ọdún 2003 nipasẹ ìlànà imudaniloju àti ìṣàkóso ènìyàn idinamọ 2003 nipasẹ agbero ti gbigbe kakiri àwọn obìnrin ati ìpilẹ̀ṣẹ̀ ipilẹ iṣẹ ọmọdé wotclef
ẹrú ní nàìjíríà nàìjíríà ní ìtàn ìsìnrú ó sì ń kópa nínú òwò ẹrú ifiranṣẹ jẹ bayi arufin ni agbaye ati ni nigeria bibẹẹkọ ofin jẹ igbagbogbo aṣemáṣe pẹlu oriṣiriṣi aṣa aṣa ti o ti wa tẹlẹ eyiti o wo awọn iṣe kan yatọ ní nàìjíríà àwọn àṣà àtọwọ́dọ́wọ́ kan àti àwọn àṣà ìsìn ti yọrí sí “ìforígbárí tí kò ṣeé yẹ̀ sílẹ̀ láàárín àṣà ìbílẹ̀ àti àwọn àṣà ìsìn gẹ́gẹ́ bí òfin orílẹ̀-èdè ní ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè ní ilẹ̀ áfíríkà” èyí tí ó ti ní agbára láti fi agbára ìdarí tí kò bófin mu lélẹ̀ lórí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbésí ayé tí ó yọrí sí òde òní -ọjọ ẹrú awọn ọna ti o wọpọ julọ ti isinru ode oni ni nigeria ni gbigbe kakiri eniyan ati iṣẹ ọmọ nítorí pé ìsìnrú òde òní ṣòro láti dá mọ̀ ó ti ṣòro láti gbógun ti àṣà yìí láìka ìsapá àgbáyé àti ti orílẹ̀-èdè sí awọn itan ti eru ni nigeria iṣowo ibile ni gusu naijiria ṣaju dide ti ipa ilu yuroopu o si tẹsiwaju ni agbegbe ni pipẹ lẹhin imukuro imunadoko ti ifi ni ọpọlọpọ awọn orilẹ-ede miiran igbo awon igbo won maintain the osu caste system ti odinani religion sokoto caliphate sokoto caliphate jẹ ile-igbimọ musulumi sunni ti o lagbara ni ọrundun 19th pẹlu olu-ilu rẹ sokoto ti o wa ni ariwa orilẹ-ede naijiria yoruba awon eru ti wa laaarin awon omo yoruba ni ibile ki a to pa a run ni odun 1893 lasiko ijoba amunisin britani
smuggling of migrants in nigeria ṣíṣe fàyàwó àwọn ènìyàn láti ìlú nàìjíríà sí òmíràn kì í ṣe ohun àjòjì ní àgbáyé kọ́dà kò yọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà sílẹ̀ àwọn obìnrin ọmọbìnrin ọmọdé àti àwọn ọ̀dọ́ ni wọ́n máa farakaáṣá ìwà ìgbéni lọ sí ìlú mìíràn ní ọ̀nà àìtọ́ àti òwò títa ènìyàn kì í ṣe òkè òkun nìkan ni wọ́n ń kó àwọn ènìyàn wọ̀ lọ́nà àìtọ́ ìwà ìbàjẹ́ yìí náà máa ń ṣẹlẹ̀ láàárín orílẹ̀-èdè nàìjíríà ṣíṣẹ fàyàwó àwọn ẹ̀nìyàn láti ibìkan lọ sí ibòmíràn ṣíṣe fàyàwọ́ àwọn ènìyàn láti ibìkan lọ sí ibòmíràn jẹ́ ọ̀nà àìtọ́ tí àwọn ènìyàn ń gbà wá owó ní pa gbígbé àwọn ènìyàn wọ ìlú tí kì í ṣe ìlú wọn lọ́nà àìtọ́ lára àwọn òfin tí ó de ṣíṣị́ kúrò láti ìlú kan sí òmíràn kò fi àyè gba kí ẹ̀nìyàn wọ ìlú ní ọ̀nà tí kò bá òfin mu tàbí kí ènìyàn máa gbe nínú ìlú láìní ìwé ìgbé ìlú gẹ́gẹ́ bí ohun tí àjọ united nations un gbogbo orílẹ̀-èdè ni àwọn àmòòkùn-ṣèkà yìí ń kó àwọn èniyàn wọ̀ ní ọ̀nà àìtọ́ wọ́n tẹ́sìwájú láti jẹ́kí amọ̀ pé àwọn tí wọ́n ń lọ sí ìlú mìíràn ní ọ̀nà àìtọ́ ṣí sí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ewu ẹgbẹ̀rún àwọn ènìyàn ní wọ́n tí kú sí aṣálẹ̀ àwọn mìíràn sí rì sí inú omi nípa sẹ̀ pé wọ́n fẹ́ wọ ìlú onílùú ní ọ̀nà àìtọ́ ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà ló ti pàdánù èmí wọn láti pasẹ̀ àìnímọ̀ tàbí mímọ̀ọ́mọ̀ fẹ́ wọ ìlú ònílùú ní ọ̀nà àìtọ́ gẹ́gẹ́ bí ohun tí àjọ unodc united nations office on drugs and crimes sọ wọ́n kò dátà tó tó láti lè mo iyẹ àwọn ènìyàn tí wọn wọ ìlú ní ọ̀nà àìtọ́ àti ọ̀nà tí àwọn tí ó ń ko wọ́n wọlé ń gbà ìgbésẹ̀ tí nàìjíríà ń gbé láti kojú ìwà gbígbé àwọn ènìyàn láti ìlú kan sí òmíràn lónà àìtọ́ nítorí bí ewu tó wà nínú kíkó àwọn ènìyàn wọ ìlú mìíràn lọ́nà àìtọ́ ló mú kí àwọn aláṣẹ orílè-èdè nàìjíríà ó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn unodc láti ara iṣé àkànṣe starsom “ orilẹ̀-èdè nàìjíríà ti ní àwọn ohun to tọ́ láti kojú ìjà sí ìkóni-wọ-ìlú lọ́nà àìtọ́ pẹ̀lú àtìlẹ́yì naptip “àwọn amọ̀fin àti ọlọ́pàá ń bójútó àwọn ẹ̀ṣọ́ tó ń mójútó ọ̀nà wíwọ inú ìlú àti gbígbé inú ìlú ní àwọn ààlà orílẹ̀-èdè nàìjíríà àti àwọn ìlú tó jẹ́ ibùgbé fún àwọn akóní-wọ-ìlú lọ́nà àìtọ́ ni orílẹ̀-èdè nàìjíríà àti ghana àjọ unodc ìwádìí fihàn pé àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́ yìí máa ń ní ètò tí ó pé láti kọjá sí niger ọkọ̀ ìrìnsẹ̀ ojoojúmó ní wọ́n ń lò láti kó wọ́n lọ sí apá àríwá kí wọ́n to fi ẹsẹ̀ wọ niger kí ọ̀kan lára agbẹ́ni-wọ̀lú lọ́nà àìtọ́ tó wá bá wọn lára
nigeria sexual offenders and service provider database nigeria sexual offenders and service provider database tí ó wà lábẹ́ ìṣàkóso naptip jẹ́ olùpèsè iṣẹ́ tó ní ojúṣe láti ṣe àtòjọ àti àkọsílẹ̀ orúkọ àwọn èèyàn tí wọ́n ti fi ẹ̀sùn ìwà-ipá kàn àti ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn wọ́n gan-an àwọn èèyàn tó bá ti lòdì sí àwọn òfin tó wà lábẹ́ section 44 nínú ìwé àkójọpọ̀ òfin orílẹ̀-èdè naijiria ni àjọ yìí máa ń ohun tí àwọn òfin yìí wà fún gan-an ni ìtàn ọdún 2015 ni wọ́n gbé ètò yìí kalẹ̀ lábẹ́ òfin tó ń rí sí dídí ìwà-ipá lọ́wọ́ ààrẹ goodluck jonathan ló sì bọwọ́ lu ìwé yìí kí wọ́n tó gbétò yìí kalẹ̀ lọ́dún 2019 àkọsílẹ̀ méjì péré ni ó wà fún ṣíṣe àtòjọ orúkọ àwọn èèyàn tí wọ́n ti fi ẹ̀sùn ìwà-ipá kàn àwọn ìwé náà ni the sexual offenders registry ní ipinle eko àti the black book ìpínlẹ̀ èkìtì àwọn abala àkọsílẹ̀ àwọn abala àkọsílẹ̀ tí ó wà ni
nigeria immigration service wọ́n ṣẹ̀dá àjọ nigeria immigration service nis àjọ aṣọ́bodè ìrìnkèrindò àwọn ènìyàn láti ara àjọ ọlọ́pàá the nigeria police np lóṣù kẹjọ ọdún 1958 ní ìbẹ̀rẹ̀ wọ́n ń pè wọ́n ní immigration department chief federal immigration officer cfio ni ó ń darí wọn nígbà náà ìdásílẹ̀ wọ́n dá ẹ̀ka aṣọ́bodè ìrìnkèrindò àwọn ènìyàn the immigration department sílẹ̀ pẹ̀lú òfin act of parliament cap 171 laws of the federation of nigeria lọ́jọ́ kìíní lóṣù kẹjọ ọdún 1963 lásìkò tí alhaji shehu shagari jẹ́ mínísítà iṣẹ́ abẹ́lé minister of interior tí wọ́n ń pè ní ministry of internal affairs lásìkò náà ní ìbẹ̀rẹ̀ òfin tí ó ń darí iṣẹ́ àjọ aṣọ́bodè ìrìnkèrindò àwọn ènìyàn ni òfin immigration act ti ọdún 1963 tí wọ́n ṣàtúnṣe sí lọ́dún 2014 àti 2015 immigration act 2015 ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìyípadà àti àtúnṣe ló ti dé bá àjọ aṣọ́bodè ìrìnkèrindò àwọn ènìyàn láti ọdún 1963 tí wọ́n ti dá a sílẹ̀ títí di àkókò yìí tí ó fi bá ìṣe ìgbàlódé mú bí i tọjọ́ òní oríṣiríṣi ìyípadà ni ó ti dé bá àjọ nis pàápàá jù lọ nípa lílo ìmọ̀ ẹ́rọ ìbára-ẹnisọ̀rọ̀ òde òní púpọ̀ nínú àwọn iṣẹ́ àti àwọn ìlànà wọn ní wọ́n tí ń fi ìmọ̀-ẹ́rọ ìgbàlódé ṣe lára wọn ni lábẹ́ ìlànà abala kejì ti òfin tí ó gbé òfin àjọ aṣọ́bodè ìrìnkèrindò àwọn ènìyàn ró a ró àjọ yìí lágbára láti ṣe àwọn iṣẹ́ wọ̀nyí àwọn adarí láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ àwọn wọ̀nyí ni wọ́n tí dárí àjọ nigeria immigration service
talkam sọrọsoke talkam jẹ́ ìpilẹ̀sẹ̀ devatop centre for africa development ibùdó tó ń jà fún ètọ́ ọmọ ènìyàn tí ó gúnwá sí orí ìtàkùn ayélujára tí ó ń pèsè ọ̀pọ̀lọpọ̀ àlàyé àti dátà lórí kíkó àwọn ènìyàn ní ọ̀nà àìtọ́ àti jíjà fún ẹ̀tọ́ àwọn ẹgbẹ́ láwùjọ ilé -iṣẹ́ àwọn amòyè fún ìdàgbàsókè àwọn ajìjàgbara fún ẹ̀tọ́ ọmọ ènìyàn àwọn agbófinró àti àwọn àjọ tó ń sojú ìjọba talkam jẹ́ èdè pidgin tí ó túmọ̀ sí sọ̀rọ̀sókè' ó kún fún àwọn wọ̀nyìí ohun èlò ìròyìn ayélujára ètò ajàfẹ́ẹ̀tọ́ lórí ẹ̀rọ asọ̀rọ̀mágbèsì ní ọ̀sẹ̀ẹ̀sẹ̀ ìsàkóso ọ̀ràn tí óbá sẹlẹ̀ nọ́m̀bà tí a le yára pè whatsapp ìpolongo lágbègbè àti ìdánilẹ́ẹ̀kọ pèlu ohun èlò ìròyìn ayélujára ó rọrùn fún àwọn ènìyàn káàkiri orílẹ̀ èdè nàíjírìà láti kàn sìwa lórí ọ̀ràn tí ó bá sẹlẹ̀ níbì kan lẹ́yìí tí à ń se ìsàkóso àti àmójútó fún ẹni tí ó ń jìyá ìpalára ohun èlò ìròyìn ayélujára àti ètò lórí asọ̀rọ̀mágbèsì ti di gbajúgbajà láwùjọ láti lè máa lọgun ìlòkulò àwọn ènìyàn ní ọdún 2018 ibùdó yìí ṣe ìsirò àwọn ènìyàn tó ń gbé ní oko ẹrú ìgbàlódé jẹ́ mílíọ̀nù kan lé ní ẹ́ẹ̀rin dín láádọ́rúùn lé ní ọ̀ọ̀dúnrún 1 386000 ìwòtun rẹ j́ẹ́ méje lé pẹ́sẹ́pẹ́sẹ́ ní́nú́ ẹgbẹ̀rún kan 765 in 1000 nígbàtí ìwòtún àwọn tó le è ńi ìpalára wíwà lóko ẹrú ìgbàlódé jẹ́ ẹ́ẹ̀rìn lé láàdọ́rin lé pẹ́sẹ́pẹ́sẹ́ 7407/100 ọ́f́iìsì wọn wà ní zone 2 municipal council 22 koforidua st wuse 90028 àbújá
anthony ojukwu anthony okechukwu ojukwu je agbẹjọro ọmọ orilẹ-ede naijiria ati akowe agba ti national human rights commission ti naijiria ni ọdun 2021 o fun ni agbẹjọro agba ti nigeria san eko ni 1998 o pari masters degree llm ni ofin ni university of lagos akoka ojukwu tun pari eto international human rights training program ihrtp ni ilu canada ni ọdun 2007 ise anthony ojukwu ni won yan gege bi akowe ipinle nec ni ipinle imo ni 2001 a yàn ọ gẹgẹbi oluranlọwọ pataki si akowe alaṣẹ ti iṣaaju ti national human rights commission mfr lẹyin naa ni wọn yan ojukwu o si yan gẹgẹ bi akowe alase ti national human rights commission nipasẹ aare muhammadu buhari ni oṣu kejila ọdun 2021
olajumoke adenowo olukowe àti oluyaworan ní nàìjíríà ọlájùmọ̀kẹ́ adénọ́wọ̀ tí a bí ní ojó kerindinlogun osù kewa odun 196816 october 1968 jé ayaworan iléarchitect omo bíbi orílè-èdè nàìjíríà obere ilé isé tí ó ún yáwòrán ilé tí ósì ún se inú ilé loso rè ní odun 1994 orúko ilé isé náà ní ad consulting orúko oko rè ni olukorede adenowo wón bí omokurin méjì àárò ayé àti èkó re abí ọlájùmọ̀kẹ́ adénọ́wọ̀ sí ìlú ibadan ìpinlè oyo ni orílè-èdè nàìjíríà àwon òbí rè méjèjì jé òjògbón bàbá rè jé ojogbon ninú ìtàn ìyá rè sì jé ojogbon ninú criminology ógbé nínú ogbà yunifásitì ti obafemi awolowo obere ìwé kika ní yunifásitì náà nígbanígbà tí ó jé omo odun merinla ósì keko gboye nínú imo sayensi pèlú eye nínú ìmò iyaworan iléarchitecture léyìn odun marun ó tèsíwájú si láti àmì-èye master ní iyaworan ilé ní yunifásitì kanáà
edo state taskforce against human trafficking etaht edo state task force against human trafficking etaht jẹ́ àjọ-agbófinró orílẹ̀ èdè nigeria tí ìjọba ìpínlẹ̀ edó gbé kalẹ̀ láti dènà kíkó ọmọ ènìyàn lọ sókè òkun lọ́nà àìtọ́ pẹ̀lú àwọn orúkọ burúkú tí ó pèlé e ní ìpínlè náà ní báyìí àwọn ìpínlẹ̀ mìíràn bí i oǹdó ọ̀yọ́ èkó enugu ekiti àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ tí wo àwòkọ́ṣe ìpínlẹ̀ edo láti dá àjọ agbófinró lórí ìwà ìbàjẹ́ kíkó ọmọ ènìyàn ròkè òkun lọ́nà àìtọ́ sílẹ̀ ọ̀jọ̀gbọ́n yinka omirogbe ọ̀gá-àgbà àwọn adájọ́ àti kọmíṣọ́nnà fún ètò ìdájọ́ ní ìpínlẹ̀ edo ni alága àjọ-agbófinró náà lọ́dún 2017 gómìnà godwin obaseki ṣe ìfilọ́lẹ̀ àjọ-agbófinró tó ń tako kiko ọmọ ènìyàn ròkè òkun lọ́nà àìtọ́ ní ìpínlè náà wọ́n ṣe ìfilọ́lẹ̀ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ àjọ náà nílé ìṣèjọba ìpínlẹ̀ ẹdó ní ìlú benin tí ó jẹ́ olú-ìlú ìpínlẹ̀ náà àjọ edo task force against human trafficking ni a gbọ́ pé ó ti gba àwọn arìnrìn-àjò lọ́nà àìtọ́ tó tó 5619 padà láti orílẹ̀ èdè libya tí wọ́n ń gbìyànjú láti ròkè òkun sí ilẹ̀ europe láti ọdún 2017 títí asiko yìí wọ́n dá àjọ-agbofinro yìí sílẹ̀ pẹ̀lú aṣojú láti àjọ agbófinró lorisirisi àwọn àjọ tí kìí ṣe tí ìjọba ngos àjọ naptip mdas àjọ àwọn ẹ̀sìn gbogbo àwọn àfojúsùn láti fòpin sí òwò-ẹrú ìgbàlódé tí wọ́n ń pè ní kíkó àwọn ọmọ ènìyàn ròkè òkun lọ́nà àìtọ́ àti rí i pé wọ́n ran àwọn ènìyàn tí wọ́n gbà padà láti gbé ìgbé ayé tó dára láwùjọ
devatop centre for africa development devatop centre for africa development jẹ́ àjọ tí àwọn olùdarí wọn jẹ́ ọ̀dọ́ tí àfojúsùn wọn ò dá lórí ajọ̀ àìlérè tó ń gbógun ti kíkó àwọn ènìyàn lọ sókè òkun lọ́nà àìtọ́ ìwà ipá tí orísun jẹ́ ẹ̀yà-ìbí lílọ ọmọ ní lìlòkulò fífún àwọn ọmọ tí ó ní àǹfààní ẹ̀kọ́ ní ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ àti dídán àwọn obìnrin àti ọ̀dọ́ lóówò àjọ yìí jẹ́ àjọ tó síwájú ní ígbógun kíkó ènìyàn lo sókè òkun lọ́nà àìtọ́ ṣíṣe àwọn ètò ẹ̀kọ́ ní orí lé-èdè nàìjíríà àjọ yìí ti forúkọ wọn lẹ̀ fún àjọ cooperate affairs commission nigeria àti ní ipa lórí mílíọ̀nù ènìyàn látara ẹ̀kọ́ ìlanilọ́ọ̀yẹ̀ ìrànlọ́wọ́ fífún ni lẹ́bùn àti gbígbé ohun jáde nípa lílo èrò ayárabíàṣá itan àjo devatop centre bẹ̀rẹ̀ ní ọdún 2013 gẹ́gẹ́ bi national youth service community development project láti ọwọ́ joseph osuigwe chidiebere lẹ́yìn tí osuigwe pàdé àwọn ènìyàn tí wọ́n ti lo ipá yìí fún ó yà á lẹ́nu púpọ nípa àwọn ènìyàn tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí ní orílé-èdè nàìjíríà àti wí pé èyi mú u lọ́kàn láti dá àjọ tí ó ma kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwon ọ̀dọ́àwọn ọmọdé àwọn onímọ̀ àti àwọn obìnrin nípa ìwà ìbàjẹ́ yìí ó fọwọ́ṣọwọ́pọ̀ pẹ̀lu àjọ united nations office on drugs and crime unodc àti àjọ national agency for prohibition of trafficking in persons naptip láti sẹ iṣẹ́ kọ̀ńp̀á láti dá àwọn ọ̀nà púpọ̀ láti gbógun ti ìwà ìbàjẹ́ yìí ní ọdún 2014 ó dá ẹgbẹ́ àwọn ọ̀dọ́ láti ma kọ́ ìpa ribiribi yìí lọ àti láti mú ìdàgbàsókè bá àjọ devatop centre for africa development
ìfini ṣòwò nàbì sex trafficking in nigeria ìkóniṣòwò nàbì ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà jẹ́ ọ̀nà kan tí wọ́n fi ń kóni rìnrìn-àjò fini ṣòwò nàbì lọ́nà àìtọ́ ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ìkóni ṣòwò nàbì yi tun jẹ́ ọ̀nà ìfini ṣè òwò ẹrú ìgbàlódé tip ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà fí fini ṣòwò nàbì lọ́nà àìtọ́ yí ma ń mú ìpálára àti aburú tó pọ̀ wà fún ẹni tí a mu ṣòwò yìí# ẹbí rẹ̀ àti àwùjọ̀ rẹ̀ gbogbo ìkọ́ni rìnrìn-àjò lọ́nà àìtọ́ ma ń sábà dá lórí ìyanijẹ ìrẹ́nijẹ íṣẹrú àti ìfipá-múni ṣe ohun àìtọ́ pàá pàá jùlọ fífí àwọn ènìyàn tí wọ̀n bá kó rìnrìn àjò lọ́nà àìtọ́ náà ṣe òwò nàbì tí kò wá láti ọkàn wọn gẹ́gẹ́ bí òfin trafficking victims protection act of 2000 ṣe ṣe àpèjúwe rẹ̀ ni ó jẹ́ ìgbanisíṣẹ́ ìgbanimọ́ra ìpèsè fúnni ìfipá múni lọ́nà àti fífini ṣòwò nàbì lọ́nà àìtọ́ tí kò sí tọkàn ẹni wá bí ó tilẹ̀ jẹ́ wípé ìbálòpọ̀ ipá tàbí ìfiniṣòwò nàbì pẹ̀lú awọ ọmọdé tí ọjọ́ orí wọn kò tíì tó ọdún méjìdínlógún ni a lè pè ní íkóni rìnrìn-àjò lọ́nà àìtọ́ ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà àwọn ọmọdékùnrin àti áwọn ọmọdébìnrin ni wọ́n ma ń kó rìnrìn-àjò lọ́nà àìtọ́ ní kẹ̀tí-kẹ̀tì láti orílẹ̀-èdè wọn lọ sí àwọn orílẹ̀-èdè bíi italy saudi arabia north africa europe faransé spain netherlands belgium austria norwayamẹ́ríkà àti asia fún òwò nàbì bákan náà ní wọ́n tùn ń ko àwọn ọmọdékùnrin àti àwọn ọmọdébìnrin tó fi mọ àwọn ọkùnrin àti obìnrin tí wọ́n jẹ́ abilékọ rìnrìn-àjò lọ sí àwọn ìlú àti orílẹ̀-èdè tí ó wà ní ìtòsí orílẹ̀-èdè nàìjíríà chad niger republic benin republic togo àti ghana fún báárà ṣíṣe òwò nàbì iṣẹ́ ọmọ-ọ̀dọ̀ àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ iye áwọn ènìyàn tí wọ́n ń kó rìnrìn-àjò kúrò lọ́nà àìtọ́ ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà láàrín ọdún kan ma ǹ tó àádọ́talélẹ́ẹ̀dẹ́gbẹ̀rin 750000 níye nígbà tí wọ́n ń kó ìdá tí ò lé ní àádọ́rin 75 nínu wọn rìnrìn-àjò láàrì́n orílẹ̀-èdè náà bákan náà ni ìdá mẹ́tàlélógún 23 ni wọn ń ipinle kọọkan nigba ti wọn n ko ida meji ninu wọn jade kuro ni orilẹ-ede naijiria laarin ọdun kan
fatima waziri-azi fatima waziri-azi jẹ agbẹjọro ọmọ orilẹede naijiria ati olori ẹka ti ofin ara ilu tẹlẹ ni ile-ẹkọ giga ti ile-ẹkọ giga ti naijiria fatima je oluranlowo pataki fun aare orilede naijiria muhammadu buhari lati osu kejo odun 2019 ko je fije oga naptip agbẹjọro ẹtọ obinrin kan lodi si iwa-ipa abele ati ibalopọ ati alamọja ni ofin ofin fatima waziri-azi ti lọ si ile- ẹkọ giga ahmadu bello zaria ti o gba oye ninu ofin ni ọdun 2001 o tun jẹ ọmọ ẹgbẹ ẹlẹgbẹ chartered institute of arbitrators uk acirb omo egbe nigerian bar association nba omo egbe new york county lawyers association nycla ẹgbẹ association of women in development awid omo egbe women ni international aabo wiis fatima waziri-azi ṣiṣẹ bi agbẹjọro/oṣiṣẹ eto agba ni eto awọn obirin awọn ọran idibo ati iduro iyipada idajọ idajọ lati oṣu kini ọdun 2005 si oṣu kẹjọ ọdun 2006 fatima te si wa o ṣiṣẹ bi iwadii ati oṣiṣẹ eto ni igbimọ advisory president against corruption pacac lati kínní 2016 si oṣu kọkanla ọdun 2018 won yoo arabinrin wazi -azi ni ofiisi ti igbakeji alakoso ti federal republic of nigeriaṣiṣẹ gẹgẹbi oludamọran ofin fun alakoso ni ni oṣu kẹsan ọdun 2021 fatima waziri-azi ni a yan oludari gbogbogbo ti ile-ibẹwẹ ti orilẹ-ede fun idinamọ ti gbigbe kakiri ni eniyan naptip
national commission for persons with disability national commission for person with disabilities ncpd jẹ́ àjọ kan lòrìlẹ̀-èdè naijiria ọdún 2012 ni a gbé àjọ yìí sílẹ̀ èròńgbà àjọ yìí ni láti dẹ́kun ìwà yíya àwọn èèyàn tó ní àleébù tàbí ìlera sọtọ̀ àti láti jẹ́ kí irú àwọn èèyàn báyìí ní ẹ̀tọ́ àti àǹfààní kan náà pẹlú àwọn akẹgbẹ́ wọn tí ò ní àleébù kọkan lára wọ́n dá àjọ ncpd sílẹ̀ nílànà òfin ọdún 2019 tí ó ní ṣe pẹ̀lú dídẹ́kun ìwà yíya àwọn èèyàn tó ní àleébù tàbí ìlera sọtọ̀ àti láti ri pé wọ́n kópa nínú gbogbo ẹ̀ka iṣẹ́ láàárín ìlú àwọn èróńgbà wọn díẹ̀ lára àwọn èróńgbà àjọ yìí ni ìtàn ọjọ́ kẹtàdínlógún oṣù kìíní ọdún 2019 ni ààrẹ muhammadu buhari bọwọ́ lùwé láti ṣe ìdásílẹ̀ àjọ ncpd lábẹ́ òfin 2018 díẹ̀ lára àwọn ohun tí òfin yìí wà fún ni ríró àjọ yìí lágbára láti múgbòrò àti dábòòbò àwọn èèyàn tó ní àleébù tàbí ìlera
ọjọ́ ìkéde lòdì sí kíkó àwọn ènìyàn lọ sí ìlú onílùú lọ́nà àìtọ́ ní orílẹ̀-èdè europe eu anti-trafficking day eu anti-trafficking day jẹ́ ọjọ́ tí wọ́n yà sọ́tọ̀ láti kéde lòdì sí wíwọ ìlú lónà àìtọ́ ọjọ́ kejìdílógún oṣù ọ̀wàwà ni ọjọ́ ìyàsọ́tọ̀ fún ìpolongo yìí ìgbìmọ̀ europe ni wọn dá a sílẹ̀ pẹ̀lú èròngbà áti jẹ́ kí àwọn ènìyàn mọ̀ nípa ewu tí ó wà nínú kíkó àwọn ènìyàn wọ ìlú lọ́nà àìtọ́ àti títẹnumọ́ ẹ̀tọ́ àwọn afarapa láti wá ìdájọ́ tótọ́ àwọn ènìyàn gbàgbọ́ pé àṣà ìkónilẹ́rú jẹ́ ohun tó tí kọjá lẹ́yì tí wọ́n fi òpin sí i àmọ́ ó ṣeni láàánú pé èyí kò rí bẹ́ẹ̀ rárá ní tòótọ́ ó jẹ́ ohun tí kò ní òde- òní àmọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀nà tuntun ní wọn ń gbà mú àwọn èniyàn lẹ́rú lílo ọmọ fún iṣẹ́ ọmọ ọ̀dọ̀ lílo ọmọdé fún ẹ̀ṣó ológun títi ọmọdé sí ìgbéyàwò tipátipá àti bẹ́ẹ̀ lọ kò gbẹ́yìn ó jẹ́ ọjọ tí wọn yà sọ́tọ̀ láti ṣe ìrántí àwọn tí ó farakááṣá nínú kíkó àwọn ènìyàn láti ìlú kan sí òmíràn lọ́nà àìtọ́ human trafficking ìdí fún ìpolongo yìí ni lati ṣe àfikún òye ìmọ àti ìmúlò tó péye láàárí àwọn tí ó ń ṣiṣẹ ẹ̀ka yìí ọjọ́ ìkéde lòdí sí kíkó àwọn ènìyàn lọ sí onílùú lọ́nà àìtọ́ ní orílẹ̀-èdè europe wà láti ru àwọn ará ìlú sókè àti dẹ́kun ìwà ọjọ́ ìkéde lòdí sí kíkó àwọn ènìyàn lọ sí onílùú lọ́nà àìtọ́ ní orílẹ̀-èdè europe àti láàárín àwọn ènìyàn lápapọ̀
eu anti-trafficking day
women advocate research and documentation centre women advocates research and documentation centre wardc je ajo ti kii se ti ijoba ti won da sile ni odun 2000 ti wo gbogun ti iwa ipa si obinrin ati awon eniyan gbogbo ni orilẹ-ede nàìjíríà it is registered with the cooperate affairs commission nigeria and has impacted impacted women and girls in nigeria through its sensitizations activities campaigns and assistance
child labour in nigeria
child labour in nigeria ìfọmọdé ṣiṣẹ́ ipá
international and ibero-american foundation for administration and public policies àjọ international and ibero-american foundation for administration and public policies fiiapp ni ò jẹ́ àjọ gbogbo gbo tí wọ́n dá sílẹ̀ ni abe spanish state and a member institution of cooperación española lati ọwọ́ orílẹ̀-èdè spain àjọ yí ni ó ti ṣe ìkúnlápá nípa ṣíṣàgbékalẹ̀ iṣẹ́ àkànṣe oríṣiríṣi jákè-jádò àgbáyé fiiapp ni ó ń ṣiṣẹ́ labẹ àṣẹ spanish foreign policy bí ó ṣe bẹ̀rẹ̀ ajọ yi ni wọn bẹ̀rẹ̀ wọn dá silẹ̀ ní ọdún 1998 lábẹ́ orúkọ ibero-american government and public policy foundation fundación iberoamericana de gobierno ́y políticas públicas pẹ̀lú ìrankàn àti ṣíṣẹ pẹ̀lú àwọn àjọ àwùjọ gbogbo ní ọdún 2000 wọ́n jàn án pọ̀ mọ́ ibero-american institute of public administration foundation fundación instituto iberoamericano de administración pública tí wọ́n dá sílẹ̀ ní ọdún 1997 tí ó jé kí ó di international and ibero-american foundation for administration and public policies fiiapp lóní fiiapp ti di ọ̀kan gbòógì nínú àwọn àjọ tí ó ṣe agbátẹrù fún àwọn iṣẹ́ àkànṣe oríṣiríṣi fún àjọ european union ati spanish ministry of foreign affairs and cooperation ẹ tún lè wo http//wwwfiiapporg/ fiiapp international cooperation projects- http//wwwfiiapporg/proyectos/
igbeyawo ipa igbeyawo ipa je ohun kan ti owopo ni ilu naijiria ni to ri wipe ijoba apapo ati ijoba ipinle o tii fi awon ofin lele lati daa duro ni eto omode wi ilu naijiria je ilu ti igbeyawo ipa wopo ju ni ile alawo dudu eto omo eniyan ofin eto awon omode lodi si igbeyawo omo ti ko to omo odun mejidini ogun olodi si ofin ilu nigeria awon ipinle ti ofin ati ilana musulumi ti gbile kuna lati ti gba pe ofin ijoba apapo to wipe omo gbodo pe omo odun mejidi ni ogun ki o gbeyawo tabi ki o to lo si ile oko oje ohun ti o bani ninuje lati gbo pe ni nkan bi ogun odun lehin ti ijoba ti fi ofin lele nipa eto omode sibe-sibe won si n fi awon omodebinrin fun oko tipatipa ni ilu nigeria awon ijoba ipinle ni ilu naijiria gbodo bere ni pajawiri lati gba awon ofin ati ilana igbewayo wole pelu ilana ati eto awon omode ni osu kejo ati osu kewa ni odun 2021 awon osise eto omoniyan se iforowani lenu wo lati odo awon omobirin ti odun won bere lati odun merinla de mokandinlogun apapo awon ajo ti kiise ti ijoba nsise takuntakun lati ri ni aridaju wipe won fi opin si igbeyawo awon omode ati ifiyajeni ninu igbeyawo ni ipinle imo ati kano ipa awon egbe ajafeto omoniyan egbe apapo awon ti o mmoju to eto omo eniyan se asayan ipinle imo ati kano ni to ri orisihrishi asa ofin ati ilana won kowe ranshe si eka ijoba ti won mojuto awon obinrin lati le se iforo wa ni lenuwo sugbon ko si ifesipada olodi si ofin ni ilu naijiria ati ni ile alawodudu lati fi omobirin ti ko ti to omo odun mejidi ni ogun fun iyawo eri fi han wipe ni ilu imo and kano awon odomobirin oki fibe ni ominira lati ka iwe lati mojuto ilera arawon atiwipe ko fibee si abo ti onipon fun awon obinrin ninu awon odomobirin ti won fe fifun oko fi ogbon yera ni ipinle imo ti pupo ninu won nse esin christiani to je ede igbo ni won ma nso gba ofin eto awon omode wole ni odun 2004 awon odomobinrin won ni awon ebi won lo sabi ma nti won si igbeyawo ipa ninu ofin sharia ni ipinle kano eri fi han wipe ibe ni igbeyawo ipa posi ju ni orile ede nigeria ile igbimo agba ipinle kano buwo lu abadofin aabo lori awon omode ni inu osu keji odun 2021 gegebi o ti wa ni ibamu pelu ofin ati ilana awon orile-ede agbaye ni ipinle kano awon ajo ati won moju to eto omo eniyan wipe awon ebi ma nfi awon obinrin fun oko lai jeki won mo nka ti o ye ki won mo ni pa eni ti won fefe ilana ati asa igbeyawo won je nka ti oni se pelu ofin sharia ofin esin ati ofin ibile ni tori wipe awon obinrin ko ni anfani lati se ipinnu ara eni awon obi mi so wipe awon inowo ma ndiku ti won ba tete fi awon omobinrin won fun oko awon omobinrin imi ni wipe ipo nkan ma nnira fun awon lehin igbeyawo awon imi oki kawe nitori wipe kosi owo awon oko imi o kii fe ki iyawo won ma se ise osu oje ohun pajawiri fun orile ede nigeria lati se ofin lati file ma daabobo awon omobirin kuro lowo awon afipa fun ni loko ni eto omo eniyan wi ofin eto omode gbodo je ohun ti gbogbo ipinle ati eka gbodo gba towo tese won gbodo ri ni aridaju wipe gbo eyan mo nipa ohun ti ofin na wi ati iya ti won yo fi je enikeni ti oba tapa si ofin naa nitori igbeyawo ipa ti owopo ni ipinle imo ati kano ose pataki lati jeki gbogbo eniyan ni orile ede nigeria mo ni pa awon ofin ati ilana igbeyawo tobojumu ati abo to peye fun awon odomobinrin ni orile ede nigeria fun awon eri aridaju ati ayewo to peye ale kansi ifipa fo mobinrin foko ni orile ede nigeria asa ni ilana esin ati asa ifipa fo mo fun igbeyawo je ohun ti owo po ni orile nigeria ju ilu kilu lo ni ile alawodudu agbajopo ijoba agbaye ni ipade won ni odun 2020 wipe ida metalelogoji awon odomobinrin ti won je omo odun ogun ati merinlelogun ni won ti fifun igbeyawo ni orile ede nigeria ifipa fi obinrin fun oko je ohun ti ma ni damu won ni gbogbo ona ni igbesi aye won ijoba orile ede nigeria ati ijoba ipinle ni ipa ti won gbodo ko pelu agbajopo ijoba ile alawodudu and agbajopo ijoba kari agbaye gege bi ofin ti wi ipinle mokanla ninu ipinle mefalelogbon ni orile ede nigeria ni won ko ti gba ofin eto omode wole si ipinle won ilana ati ofin isin musulumi ni awo ariwa na tun dakun popo ninu isoro fifi awon odomobirin kekee fun oko ati asa idabe pelu gbogbo isapa orile ede nigeria lari ri pe won se ohun gbogbo ni ilana ati ofin agbaye eri fi han wipe ni ilu ariwa ni orile ede nigeria ida mejidi ni ogorin awon obinrin ti ma si ile oko ki won to di omodun mejidiniogun awon egbe to mo ju to eto omo eniyan se awaridaju lodo awon elesin musulumi eka ariwa ati elesin christiani ni eka gusu orile ede nigeria wipe eto nlo ni ilu kano lati ri ni aridaju wipe abo to peye wa fun awon odomobirin atipe wipe won gbodo da asha fifi awon odomobinrin to won ti pe odun mejidilogun foko ni idaduro awon asofin gbodo sapa lati ri wipe awon ofin won fi aye fun idaabobo awon ti won je omodun mejidiniogun https//wwwvanguardngrcom/2021/02/kano-approves-child-rights-act-awaits-passage-of-bill-from-assembly/ ipinle imo je okan lara ipinle ti won koko gba asa eto awon omode wole ni ojo kerin osu kejo odun 2014 ede igbo ni won ma nso ni ilu imo pupo niniu won ni won ma nse esin christiani eri fi han wipe won ti pari ise won nipa didabobo won odomobirin kuro lowo awon afipa foko fun ni ni ilu imo oje ohun ti olodi si ofin ibile fun obinrin lati loyun lai loko to ba si ti ri be won ni lati wa okunrin agbalagba fun to onfe lati fe iyawo ki omo won le ni baba opolopo awon odomobinrin ti won fi fun oko lehin igba ti won ti loyun ni awon obi won ni wipe won ti ba asa ati ise ibile je won ko si ni fi aye sile fun awon ebi won lati gba owo ori won racheal je odomobinrin omo marundinlogun lati ilu imo ore kun re fun ni oyun nigba ti osi nlo si ile iwe grammar lowo osa jade lati ma lo gbe ninu ile alakoku fun ose meji lai le pada si ilewe mo mosa jade nitori iberu pe mo loyun nitori wipe isoro yen yo ti poju ti mo ba ngbe pelu awon molebi mi asemi ni anfani tim nmba fe oko pelu iranlowo awon egbon ati aburo re o ma npa da sile ni nkan bi agogo meji oru lati wa je onje ale nigba ti ibinu awon obi re bati lole die lehin igba ti orekunrin ti o fun loyun jaakule awon obire wa oko miran fun latin pa oruko idile won mo lai pe osu kan ofe okunrin kan to o je omo ogbon odun to san naira marundin ni ogun fun awon obi re gege bi owo ori owun ati odomokunrin naa ko ri ra won ri titi nkan be ose meji si ojo igbeyawo won odomokunrin na ni mo fi oju kan ni igba akoko ni ile baba mo si bere lowo iya mi pe tani eniyen iya mi wipe oko mi niyen omo ogbon odun ni mi o ni ni anfani lati maa gbe ile awon obi mi mo pelu awon omo mi odidandan fun mi lati lo maa gbe pelu oko mi mi o si fe si odomobinrin obinna je omo odun marundinlogun eni to funloyun je oluko ni ileiwe re omodun ogota ni igba ti o nlo si ile iwe grammar awon obi re dawo riran lo si ile iwe duro won si le si ita
drug trafficking in nigeria òwò gbígbé oògùn-olóró lọ sí ilẹ̀ mìíràn láti tà á jẹ́ ẹ̀sẹ̀ tó lágbára ni orílé èdè nàìjíríà ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn ló rí iṣẹ́ yìí bí i òwò tó lérè lóri àwọn ọ̀daràn ènìyàn ló máa ń ṣiṣẹ́ yìí èyí fi hàn wí pé kò kì í ṣe àwọn nìkan lọ máa ń mú lọ sókè òkun láti fi ṣìwò burúkú yìí èyí ti di ohun ìbàjẹ́ láwùjọ wa débi wí pé àwọn ènìyàn tí à ń fi ojú wò gan-an ti ń ṣe é àwọn ènìyàn bí àlùfáà páṣítọ̀ àti àwọn ènìyàn ńláńlá mìíràn òwò yìí ti jẹ́ ọ̀nà kíkówójọ fún àwọn ọ̀wọ́ ọ̀daràn púpọ̀ tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọwọ́ yìí tì ń kópa nínú àwọn ìwà ìbàjẹ́ bí i dídigunjalè sísọ àwọn ọmọ ènìyàn di ẹrú àti ẹ̀ṣẹ̀ onírìnàjò láti ìlú kan sí òmíràn
ilokulo omo obinrin ni orile ede naijiriagirls child labour in nigeria ìlòkulò ọmọ obìnrin ní orílẹ èdè nàìjíríà jẹ́ ìsẹ̀lẹ̀ tó ń sẹlẹ̀ sí ọmọ obìnrin tó wà láàrin ọdún máàrún sí mẹ́rìnlá tó ń lọ́wọ́ sí akitiyan ọrọ̀ ajé yàtò sí ẹ̀kọ́ ìwé àti ̀igbà ìsinmi wọn lílo ọmọbìnrin ní ìlòkulò ní orílẹ̀ èdè nàìjíríà ti di ìwà ìbàjẹ́ tó tànkálẹ̀ látàrí ọrọ̀ inú ilé sùgbọ́́n àwọn okùnfà míràn bíi àseyọrí ètò ẹ̀kọ́ ìpele ẹ̀kọ́ òbí ẹgbẹ́ aláàbárìn ìbéèrè fún alábásisẹ́ nínú ilé àti òsìsẹ́ alábálòpọ̀ gbogbo eléyìí ló ń sokùn fa tí ìlòkulò ọmọ obìnrin se pọ ní orílẹ̀ èdè nàìjíríà láfikún ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwùjọ ìgbèríko àti mùsùlúmí ní ariwa orílẹ̀ èdè nàìjíríànígbàmíràn wọn a máa rán àwọn ọmọdé tàbí obìnrin ẹléhàá nísẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọ̀dọ́mọdébìnrin yìí a máa ṣiṣẹ́ gẹǵẹ́ bíi olùrànlọ́wọ́ nínú ilé olùrànlọ́wọ́ ilé ìtajà oníkiri ọjà lójú pópó lílo àwọn ọ̀dọ́mọdébìnrin nínú akitiyan ètò ọrọ̀ ajé ti fi wọ́n hàn sí ewu ìbálòpọ̀ àìrí ìtójú látọ̀dọ̀ òbí àti ìlòkulò láfikúniṣẹ wọn yìí kò lẹ́ẹ̀tó lábé òfin àti pé kò ní ànfààní kankan gẹ́gẹ́ bíi òṣìṣẹ́ ńi orílẹ̀ èdè nàìjíríààwọn okùnfà bíi òsì àti àìríṣẹ́ṣe òbíìsílo kúrò ní ìgbèríko sí ìlú ìwọ̀n ẹbí tí ó tóbiàwọn àsà bíi ìlóbìnrin púpọ̀ jẹ́ orírun fún ìlòkulò ọmọ àwọn èyí tí ó jẹyọ láti àwùjọ iye ènìyàn àti ọrọ̀ ajé àwọn okùnfà míràn ni ilé ẹ̀kọ́ pínpín tó kéré àìrí àyẹ̀wò àti iye owó ẹ̀kọ́ tó gaara síwájú síi láìpẹ́ ìjà àti ìgbésùnmọ̀mí ti fa ìyípadà lábẹ́nú fún àwọn ènìyànìbàjẹ́ ohun èlò ilé ẹ̀kọ́ àti mímú àwọn ọmọ lọ fún ìlòkulòjùbẹ́́ẹ̀loọ̀pọ̀ ìpànìyàn láwùjọ látowọ́ àwọn kanranjọ́ngbọ́n agbésùnmoọ̀mi ́ní àríwá orílẹ̀ èdè nàìjíríà ti sokùnfà pípọ̀ àwọn ọmọ òrukàn àti àwọn ọmọ tó ń jìyà ìpalára látàrí ìlòkulò
bella disu oníṣòwò ní nàìjíríàwọ́n bi ní ọdun 1986 belinda bella ajoke olubunmi disu orúkọ baba rẹ̀ ni adenuga wọ́n bí ní 29 may 1986 jé obinrin onísòwò omo nàìjirià òun ni alaga abumet tnigeria limited ígbákejì alaga ilé ise globacom oun sì tún ni oga agba cobble stone property and estate limited ati alaga julius berger nigeria plc àárò ayé àti èkó rè a bí bella disu ní 29 may 1986 sí inú idile mike adenugaalaga globacom àti emelia adefolake okawe ní ìlú eko ilé ìwé akobere rè ní ilé-ìwé corona victoria highland ósì lo ilé-ìwé queen's college fún èkó sekondiri rè ní odun 1998 ófi ilé-ìwé queen's college kale láti lo si ilé-ìwé vivian fowler memorian college for girls nibi tí o ti pari ìwé sekondiri ní odun 2000 ogba àmì-èye bachelor degree ní sayensi oselu àti international relations ní yunifásitì ti massachusettsìlú amerika ósì tún gba àmì-èye msc ninú leadership ní yunifásitì ti northeastern boston isé rè ní odun 2004 bella darapò mó ilé ise globacom ltd ósì ti di ara àwon oludari ilé isé náà ní odun 2011 o di òkan ninú àwon egbe oludari cobblesrone estate and property ltd ósì di ògá àgbà ilé isé náà ní odun 2015 ó tún jé oludari fún ilé isé julius berger tí èka nàìjíríà àti oludari abamet plc ilé isé tí óún se gilasi àti aluminum ní nàìjíríà ní osù kiní odun 2019 ó di ígbákejì alaga ilé isé globacom ìdílé rè ní osù kerin odun 2010 bella fé jameel disu wón sì bí omo méjì àmì èye ní december 2019 ìjoba french fún bella ní àmì èye ordre des arts et des lettres fún ìkópa ré nínú itoju art àti asa papajulo imojuto construction of the alliance francaise mike adenuga centre ikoyi tí eko
sex trafficking in nigeria
lara george lara george tí a bí ní 25th of june 1978 jé olorin ihinrere omo bíbí ìlú nàìjirià sùgbón tí ó ún gbé ní ìlú amerika àárò ayé rè a bí lara george ní june 25 1978 sí idile oluwole bajomo ni ipinle lagos ipin iṣakoso ti nigeria ìwè rè ó kàwé ni ilé-ìwé queen's college ni èkó tí ó tó di pé ó kàwé ní yunifásitì ìlú èkó ìbí tí ó tí gba master degree ní iyaworan iléarchitecture isé re lara bèrè orin kíko nígba tí ó wà ní yunifásitì ìlú èkó níbi tí o ti darapo mó àwon akorin apejopo ara ówà lára àwon egbe akorintí a padà tua tí à ún pè ní kush ara àwon orin tí lara kókó gbé jáde ni ìjoba orunní odun 2008 orin náà gbajugbaja nile loko ósì mú òpòlopò ami eye wa fún
killing of baby p
derek bentley case derek william bentley 30 osu kefa ọdun 1933 28 oṣu kini ọdun 1953 jẹ ọkunrin ara ilu gẹẹsi kan ti a pa nipa siso o ro titi emi fi bo ni enu re fun ipaniyan ọlọpa kan lakoko igbiyanju idigun jale kan christopher craig ẹni ọdun mokan din l'ogun ti o je ọrẹ ati alabaṣiṣẹpọ bentley ni a fi ẹsun ipaniyan naa kan bentley fi idi re mule wipe bentley jẹbi ẹsun kikopa ninu itapa si ofin naa nipasẹ ilana ofin kan ninu iwe ofin ile gẹẹsi ti a mo si “ ifọwọsowọpọ ” nitori wipe iwa idigun jale yi ni a se pelu isokan idajo naa ko wa ni isokan awọn igbimo idajo ti a gbe kale fi idi re mule wipe bentley jẹbi esun ti a fi kann lori itumo ti agbejoro ijoba fun oro kan ti bentley so wipe jẹ ki o gbaa iyanju ti bentley fun craig ti a ko si le fi itumo re lele ni pato tabi idaniloju leyin ti onidajọoloye goddard ti ṣe apejuwe bentley gẹgẹbi eni ti o se iranlọwọ ọpọlọ ninu ipaniyan sidney milesgoddard ṣe idajọ iku fun bentley nipa siso ro titi ti emi yi o fi bo ni enu re lai bikita fun idirebe awon igbimo idajo lati dari ji arakunrin naa labẹ idajọ ti ofin iku 1823 ko si idajo miiran ti o ṣee ṣe biotilejepe ofin ipaniyan 1957 eyiti o ṣafihan awọn aabo ojuse ti o dinbiotilejepe ofin ipaniyan 1957 eyiti o ṣafihan awọn aabo ojuse ti o dinku ti o lagbara ti fẹrẹẹ jẹ ipa nipasẹ ejo bentley yi ẹjọ bentley yi di mimo kaakiri ilu ti o fi je wipe o yori si ipolongo ọdun marun din laadota lati gba idariji fun derek bentley lẹhin iku re eyiti o di sise ni ọdun 1993 pelu ipolongo lati pa ejo iku ti pa ejo iku ti a da fun rẹ eyiti o waye ni ọdun 1998 nitoribẹẹ ọran rẹ yi ni a ka si ọran ti ilodi si idajọ pelu ejo ti timothy evans eyi ti o si je idi kan pataki ninu aṣeyọri ipolongo lati fopin si ijiya iku ni ile geesi ibere igbesi aye re derek bentley wo ile iwe norbury manor secondary modern school ni odun 1944leyin igba ti o ti idi r'emi ninu idanwo awon omo odun mokanla soke ki o to pari ninu osu marchodun 1948bentley ati omodekunrin kan ni a awon olopa fi kele ofin gbe fun esun ole leyin osu mefa a da won lejo lati lo se ewon odun meta ni kingswood approved schoolleba bristolchristopher craig naa je akeko ni ile iwe secondary modern school yi ilera ati idagbasoke ti opolo derek bentley ni opolopo awọn iṣoro idagbasoke ilera awọn obi rẹ royin wipe ninu ijamba kekere kan ni o ti fọ imu rẹ ati wipe lati naa naa o ni ijagba mẹta okan ninu eyiti wọn sọ pe o fẹrẹ gba emi re ebi naa tun sọ wipe emeta otooto ni a fi ado oloro le won jade lakoko ogun agbaye ii ati wipe ninu ọkan ninu awọn iṣẹlẹ wọnyi ile ti o ngbe wó moo lori ṣugbọn ile-ẹjọ ko rii itọkasi kanka wipe o fi ara pa naa 102 a ran bentley lo si ile-iwe ikẹkọ kingwood bristol ni ọjọ keta din logbon oṣu kẹwa ọdun 1948 wọ́n ṣe àyẹ̀wò fún un ní asiko to fi í s'ẹ́wọ̀n níbẹ̀ ni oṣu kejila ọdun 1948 nigbati o jẹ ọmọ ọdun meedogun ati abo ọjọ ori ọpọlọ rẹ ni koju ti omo ọdun mewa ati oṣu mẹrin lo nigbati o gba 66 ninu opolo kan awọn oṣiṣẹ kingwood royin pe o jẹ “ọlẹ alaibikita olufokansi ati ti iru 'alarekereke eniyan'” ti ile-ẹjọ si ṣe apejuwe rẹ gẹgẹbi “alaibikita eni ti nkan ko jo loju ati eni ti o setan lati sọ awọn itan” lẹhin igba i a fi kele ofin gbe ni oṣu kọkanla ọdun 1952 a tun se awọn idanwo opolo fun u ni ogba ewọn brixton ibi ni a ti se apejuwe re geg bi eni ti ko ni oye ti o si ni akosile 71 ninu oro siso87 ninu ise sise ati akojopo akosile ninu idanwo opolo ti o je 77 a ṣe awari pe o tun jẹ “ alaimọwe pupọ” ni akoko ti a munn ni oṣu kọkanla ọdun 1952 awon oṣiṣẹ ilera ninu ogba ewon sọ wipe “ko le ṣe idanimọ tabi kọ gbogbo awọn lẹta ti alfabeti silẹ”
kíkó àwọn ọmọ wọ orílè-èdè mìíràn lọ́nà àìtọ́ trafficking of children form of human trafficking and is defined as the recruitment transportation transfer harboring and/or receipt of a child for the purpose of exploitationkíkó àwọn ọmọ lọ sí orílẹ̀-èdè mìíràn lọ́nà àìtọ́ jẹ́ ọ̀nà kị́kó àwọn ènìyàn wọ orilẹ̀-èdè mìíràn lọ́nà àìtọ́ gẹ́gẹ́ bí àjọ united nations ṣe kì í bí i ìgbàwọlẹ́ lílọ-bíbọ̀ gbígbé láti ibìkan lọ ibò mìírán tàbí fífi sí àhámọ́ jíjí ọmọ gbé láti fi ṣẹ ẹrú ṣe iṣẹ́ agbára tipátipá àti lílò wọn nílòkulò forced labourarticle 3c nígbà mìíràn ẹ̀wẹ̀ wọn máa n kó àwọn ọmọ yìí láti kó wọn fún àwọn tí wọ́n wá ọmọ láti gbàwọn gẹ́gẹ́ bí ọmọ adoption pẹ̀lú ìṣirò àwọn àjọ international labour organization ilo wọ́n ní bí i ẹgbẹ̀rún lọ́nà mẹ́wàá ni wọ́n kó lọ́nà àìtọ́ lọ́dọ́ọdún ní ọdún 2012 àjọ united nations office on drugs and crime unodc jábọ̀ pé àwọn ìdá àwọn ọmọ tí wọ́n ń kó lọ́nà àìtọ́ tí kurò ní ogún ó ti bọ sí ẹ̀tàdínlọ́gbọ̀n láàárín ọdún mẹta gbígbé àwọn ọmọdé lọ sí òkè-òkun lọ́nà àìtọ́ jẹ́ ohun tí ó lọ̀dì sí òfin káríayé ìwà burúkú yìí máa ń wáyé ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ agbègbè ní àwọn oríléèdè lágbàáyé èyí sì máa ni ipa tí ó kó nínú ẹ̀tó ọmọ ènìyàn ní nǹkan bí ọdún mẹ́wàá sẹ́yin ni ìwà ìlòdì sí òfin yìí di ìlú-mọ̀ọ́ká nípa sẹ̀ àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tí ìwádìí gbé jáde àti ìgbésẹ̀ tí àwùjo gbé lórí ìwà àìtọ́ yìí àwọn ìwádìí tí àwọn onímọ̀ ti ṣẹ kò sọ gbogbo àwọn okùnfà gbígbé ọmọdé lọ òkè-òkun lọ́nà àìtọ́ wàyí ìṣẹ́ ogun àti àìní ẹ̀kọ́ ìwé jẹ́ okùnfà tí ó wọ́pọ̀ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọ̀nà àbáyọ ni àwọn ènìyàn tí dábàá rẹ̀ tí wọ́n sì mú lò ọ̀nà mẹ́ta ni a lè pín èyí sí àbò gbogbogbò ìdẹ́kun ìmúlò òfin àti ìrànlọ́wọ́ fún àwọn tí ó farakááṣá àwọn ìwé ìtọ́kasí <templatestyles src=refbegin/stylescss /> pmid https//semanticscholarorg/paper/4f07ac35c6a8b0390a79def965febf1a6bbdb994 https//archiveorg/details/wivesforsaleethn00mene https//archiveorg/details/elephantdragonri00mere_0
trafficking of children
kòréà
tonye garrick tonye garrick tí a bí ní 27 august 1983 tí òpòlopò ènìyàn mò sí tonye jẹ́ olorin ọmọ orílè-èdè naijiria tí a bí bi sí orílè-èdè england orin accapella rè pèlú akole what about ustí ó ko ní odun 2010 ni wọ́n lò níbi ìjíròrò ààrẹ ọ̀dọ́ nàìjíríà lọ́dún 2011 ófi isé rè kalè gégé bi olubadamoran òwò ní odun 2013 láti bèrè orin kiko àárò ayé àti èkó rè tonye je omo abinibi ilu benin ni ipinle edo orílè-èdè nàìjirià ìyá rè jé omobibi ìpínlè anambra ìyá agba rè ló fun lorukọ tamunotonye ó lo ilé-ìwé vivian fowler memorial school àti queens college ni èkó níbi tí o ti pari èkó sekondiri rè ó tèsíwájú èkó rè ní yunifásitì ti marymount
the fox and the hound the fox and the hound jẹ fílmu ti ere idaraya ará amẹ́ríkà
don jazzy michael collins ajereh tí a bí ní ọjọ́ 26 oṣù kọkànlá ọdún 1982 tí a mọ̀ mọ́ iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i don jazzyjẹ́ aṣàgbéjáde rẹ́kọ́ọ̀dù ní nàìjíríà aṣojú fún àwọn ilé-iṣẹ́ onímọ̀ ẹ̀rọ ohùn ọ̀gá ilé-iṣẹ́ orin olórin olókòwò olùsọdimímọ̀ àti adẹ́rínpòṣónú òun ni olùdásílẹ̀ àti ọ̀gá ilé iṣẹ́ mavin records don jazzy jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn tí wọ́n ni ilé-iṣẹ́ orin tí ó ti kógbá wọlé mo' hits records pẹ̀lú dbanj àbúrò rẹ̀ lọ́kùnrin ni d'prince ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ a bí don jazzy gẹ́gẹ́ bí micheal collins ajereh ní umuahia abia state ní ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n oṣù kọkànlá ọdún 1982 ọmọ ọkùnrin tí collins enebeli ajereh àti mrs ajereh bí bàbá rẹ̀ wá láti isoko ní delta state ìyá rẹ̀ jẹ́ ọmọọba igbo láti ìpínlẹ̀ abia nígbà tí bàbá rẹ̀ jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ará isoko d'prince ni àbílẹ́yìn don jazzy lọ́kùnrin ìdílé don jazzy kó lọ sí ajegunle èkó ní ibi tí wọ́n ti tọ́ don jazzy ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ àti ẹ̀kọ́ ìdílé ajereh kó lọ sí ajegunle èkó níbi tí wọ́n ti tọ́ don jazzy ó kàwé ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga takọtabo federal government college lagos ìfẹ́ tí don jazzy ní sí orin bẹ̀rẹ̀ láti ìgbà kékeré nígbà tí ó sì pé ọdún méjìlá ó bẹ̀rẹ̀ sí ni ta gìtá ó sì ń tẹ dùùrù ó tún kọ́ nípa àwọn ohun èlò orin tiwantiwa àti àwọn èyí tí ó ní okùn don jazzy lọ kọ́ ẹ̀kọ́ nípa ìmọ̀ ìmójútó okòwò ní yunifásítì ambrose alli ekpoma ìpínlẹ̀ ẹdó ní ọdún 2000 ìbátan jazzy pè é kí ó wá lu ìlù fún ìjọ agbègbè ní london èyí sì jẹ́ ìrìn àjò kìíní rẹ̀ lọ sí london don jazzy rí iṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí i abániṣọ́lé ní mcdonald's ó tẹ̀ síwájú nínú ìfẹ́ rẹ̀ sí orin ní àjọṣepọ̀ pẹ̀lú solek jjc skillz kas jesse jagz the 419 squad ati d'banj ìgbé-ayé lọ́kọláya don jazzy fẹ́ michelle jackson ní ọdún 2003 ó jẹ́ kí ó di mímọ̀ pé àwọn ní àwọn ìṣòro nípasẹ̀ bí òun ṣe jẹ́ alákínkanjú ènìyàn tí ó ń lé iṣẹ́ wọ́n sì pínyà lẹ́yìn ọdún méjì tí wọ́n ṣe ìgbéyàwó ṣùgbọ́n ṣá kò sí nínú ètò rẹ̀ láti fẹ́ ìyàwó mìíràn ní kíákíá nítorí ìbẹ̀rù rẹ̀ pé ìfẹ́ àti ìfinjì rẹ̀ fún orin lè tún dá ègbodò fún ìfẹ́ ẹlòmíràn sí í = iṣẹ́ = mo' hits records àti good music ní 2004 don jazzy fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú d'banj láti dá mo' hits records sílẹ̀ ní ọdún méjì tí ó tẹ̀le don jazzy gbé àwo no long thing àti rundown/funk you up jáde thunder fire you náà sì ti bẹ̀rẹ̀ ní àkókò náà ní àkókò yìí don jazzy bẹ̀rẹ̀ ìfarahàn tí ó jẹ́ tirẹ̀ nìkan it's don jazzy again ní ọdún 2008 don jazzy náà ní àfikún nínú àgbéjáde the entertainer láti ọwọ́ d'banj ó tún ní àfikún nínú àgbéjáde àwo wande coal mushin 2 mohits àwo tí wọ́n ṣe àpèjúwe gẹ́gẹ́ bí i ọkàn lára àwọn àwo ti ó dáńtọ́ jù tí ó ti jáde láti orílẹ̀-èdè nàìjíríà bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn àfikún don jazzy kì í ṣe gẹ́gẹ́ bí i olórin ó máa ń ṣe elégbè fún àwọn olórin tí ó gbé jáde àwọn iṣẹ́ tí ó ti ṣe ni ègbè fún àwọn olórin bí i d'banj sauce kid dr sid ikechukwu kween d'prince jay-z don jazzy ṣe ègbè fún orin kanye west lift up pẹ̀lú beyoncé nínú àwo watch the throne ní ọdún 2011 kanye west gba don jazzy síṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí i aṣàgbéjáde ohùn ní don jazzy ṣiṣẹ́ pẹ̀lú jay-z àti kanye west lórí àgbéjáde lift up tí wọ́n pe beyoncé sí nínú àwo watch the throne tí wọ́n fi síta ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kẹjọ ọdún 2011 ní oṣù kẹta ọdún 2012 don jazzy àti d'banj fìdí ìpínyà wọn múlẹ̀ pẹ̀lú ìdí ìyàtọ̀ nínú iṣẹ́-ọnà mavin records ní ọjọ́ keje oṣù karùn-ún ọdún 2012 don jazzy kéde ilé-iṣẹ́ rẹ́kọ́ọ̀dù tuntun mavin records ó ní mo rí mavin records pé yóò jẹ́ ilé agbára orin ní áfíríkà ní ìwọ̀nba àsìkò tí ó kéré jù tí ó ṣeéṣe ní ọjọ́ kẹjọ oṣù karùn-ún ọdún 2012 ó gbé àwo tí ó ní àwọn olórin tí wọ́n tọwọ́bọ̀wé pẹ̀lú ilé-iṣẹ́ orin rẹ̀ jáde àwọn orin tí wọ́n wà lórí àwo náà ni iamarachi forever oma ga take banana and chocolate yolo àti orin i'm a mavin mavin gba àwọn olórin bí i tiwa savage don jazzy gbé ìtagbà ibánidọ́ọ̀rẹ̀ tí ó pè ní marvin league dìde láti gbé ilé-iṣẹ́ rẹ̀ jáde àti láti polówó ilé-iṣẹ́ orin rẹ̀ ní ọjọ́ karùn-ún oṣù kọkànlá ọdún 2013 ajereh ní èdè àìyedè pẹ̀lú olórin rẹ̀ kan wande coal tí ó fi ilé-iṣẹ́ náà sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ méjì ní oṣù kẹsàn-án ọdún 2014 ajereh gbé orin ajàfẹ́tọ̀ọ́ àwùjọ nàìjíríà kan jáde pẹ̀lú reekado banks àti di'ja tí wọ́n pè ní arise níbi tí wọ́n ti ń gba àmì ẹ̀yẹ headies awards 2015 ajereh jiyàn pẹ̀lú olamide àwọn méjèèjì jiyàn lórí ẹni tí ó yẹ kí ó gba àmì ẹ̀yẹ next rated ó bọ́ lọ́wọ́ lil kesh ti ybnl records lọ sí ọwọ́ reekado banks tí ó jẹ́ olórin ní abẹ́ ajereh' ẹni tí ó gba àmì ẹ̀yẹ náà gba ọkọ̀ bọ̀gìnnì àwọn apá méjèèjì ni wọ́n fi ẹ̀bẹ̀ má bínú léde lẹ́yìn náà lẹ́yìn ìpínyà reekado banks kúrò ní ilé-iṣẹ́ mavin records label don jazzy sọ pé ó ṣì jẹ́ ọ̀kan lára ẹbí náà ó sì gba èróńgbà àṣeyọrí fún un bí ó ṣe ń dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ̀ fún àsìkò tí ó lò pẹ̀lú mavin records ní ọdún 2019 ó gba rema ó sì tẹ̀ síwájú láti gba ayra starr ní ọdún 2020 sí ilé-iṣẹ́ orin mavins record label ní ọdún 2021 ó kéde olórin tuntun magixx àfihàn nínú fíìmù ní ọdún 2012 don jazzy hàn nínú fíìmù moses inwang the last 3 digits in nollywood inwang tún lo àwọn òṣèré bí i ali baba ay nonso diobi àti dr sid àwọn àmì-ẹ̀yẹ ní ọjọ́ keje oṣù kẹrin ọdún 2021 ó ṣàlàyé ìdí tí kò fi gba davido sí ilé-iṣẹ́ orin rẹ̀
202021 uefa champions league
babatunde yusuf olátúnjí
d'prince charles enebeli tí a bí ní ọjọ́ kẹtàlélógún oṣù kẹwàá ọdún 1986 tí orúkọ ìnagijẹ rẹ̀ ń jẹ́ d'prince jẹ́ ọ̀kọrin afropop tí ilé naijiria ó jé olùdásílẹ̀ àti adarí ilé iṣé jonzing world ilé iṣẹ́ ìdárayá ti ó dásílẹ̀ ni ọdún 2019 ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ ìpínlẹ̀ èkó ni wọ́n bí charles enebeli sí ní ọjọ́ kẹtàlélógún oṣù kẹwàá ọdún 1986 ìdíle collins enebeli tó jẹ́ oniṣòwò àti aṣàgbéjáde orin àti olùdásílẹ̀ ilé-iṣẹ́ agbórinjáde ti sagitarious productions àti patience enebeli tó jẹ́ oniṣòwò ni wọ́ bí d'prince sí d'prince jé àbúrò don jazzy tó jẹ́ ọ̀gá ilé-iṣẹ́ mavin records orin kíkọ ò ṣàjèjì sí wọn ní ìdílé yìí ilé ni don jazzy àti d'prince bá a wọ́n tún máa ń pè é ní ọmọọba ilé-ìwé king's college ní ìpínlẹ̀ èkó ni ó ti parí ilé-ẹ̀kọ́ girama kí ó tó tẹ̀síwájú nínú ohun tó yàn láàyò iṣẹ́ tó yàn láàyò látàrí oríyìn tó gbé fún àwọn aláwòkọ́ṣe rẹ̀ tí ń ṣe fẹlá kútì àti bob marley ó pinnu láti máa lo àlòpọ̀ afrobeat àti afropop láti máa fi gbé orin rẹ́ jáde àwọn orin rẹ́ máa ń dá lórí ayé àti ohun tó ń ṣẹlẹ̀ ó sì máa ń ní ìtumọ̀ ìjìnlẹ̀ 20052012mo' hits records breakthrough single omoba wọ́n pe d'prince láti dara pọ̀ mọ̀ mo' hits records ní ọdún 2005 lẹ́yìn tí ẹ̀gbọ́n rẹ́ don jazzy dé láti uk d'prince ti gbé ọ̀pọ̀lọpọ̀ orin jáde látipa sẹ̀ mo' hits records díẹ̀ lára àwọn orin náà ni booty call cloae to you masquerade stop the violence igbe mi hey girl what you want to do to me oh no àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ jonzing world ní oṣù kẹta ọdún 2019 ó ṣe ìdásílẹ̀ ilé-iṣẹ́ agbórinjáde tirẹ̀ kalẹ̀ tí ó pè ní jonzing world
korede bello nigerian singer korede bello tí a bí ní ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù kejì ọdún 1996 ọ̀kọrin orílẹ̀-èdè nàìjíríà àti akọrin sílẹ̀ ó tẹwọ́bọ̀wé pẹ̀lú mavin records ní ọdún 2014 orin rẹ̀ godwin ló mu bọ́ sí gbangba ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé korede èyí tí ó túǹmọ́ ko ire wá jẹ́ ọmọ tí tí wọ́n bí sí ìlú èkó ibè náà ló tí ká ìwé alákọ̀bẹrẹ̀ àti ilé ìwé sẹ́kọ́ńdìrí ó bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣeré ìdárayá nígbà tí ó wá ní ọmọ ọdún méje orúkọ rẹ ní gbà náà sì ń jẹ́ african prince iṣẹ́ nígbà tí ó wá ní ilé ìwé alákọ̀bẹrẹ̀ korede bello kọ orin àkọkọ́ lẹ́yìn tí ó dá egbé kàn sílè pẹlú ọ̀rẹ rẹ̀ ó mú iṣẹ orin lokunkundu lẹyìn tí ó kó àwọn orin nínú studio ni ilé ìwé gírámà o ṣé àwó orin tí óò pé àkọlé rẹ̀ ni 'forever' èyí tí ó ẹ́ akọkọ o tẹsiwaju nínú èkó rè láti lọ mọ nípa ìmọ̀ ibi-ibaraẹnisọrọ mass communication ọ sí ní certificate higher national diploma korede bello jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ tí iléesẹ́ tí institute of information management ìsowọ́pọ̀ pẹ̀lú mavin records lẹ́yìn tí ó àwó àkọkọ́ jáde èyí tó o gbà oríyìn tí odará ní ọgá rẹ casmir uwaegbute mú hàn don jazzy èyí tí wọ́n jọ gbìmọ kọ orin mìíràn tí inú don jazzy sí dùn sí ni ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n oṣù kejì ọdún 2014 ni ó wọ mavins record lábẹ́ èyí tí o tún gbé àwọn orin tó jẹ́ gbajùmọ̀ bíi african princess àti godwin lówó lọwọ́ ó ń ṣe àkọ́kọ́ ìṣiṣẹ́ album èyí tí ó sí fí àṣà àti 2face idibia ṣe àwọn àwòrán ẹnití tí ó ń rí ìmísí láti ará orin tí wọ́n tí kò sẹ́yìn iṣẹ ọmọnìyàn kóredé bello ti ṣe awọn oríṣiríṣi iṣẹ ọmọnìyàn bí project pink blue walk fún ìmọ lori àrùn jẹjẹrẹ cancer ni ìlú abuja ni ọdún 2015 àti 2017
d prince
don jazzy
korede bello
mavin records mavin records tị́ a tún mọ̀ sí supreme mavin dynasty jẹ́ ilé-iṣẹ́ agbórin-jáde ní ilẹ̀ nàìjíríà tí don jazzy tí ń ṣe olórin àti agbórinjáde dá sílẹ̀ ní 8th may 2012 ilé-iṣẹ́ náà bẹ̀rẹ̀ lẹ́yìn tí òpin dé bá mo' hits records ilé-iṣẹ́ tí ń ṣe ti d'banj àti ti agbórinjáde tí a dárúkọ ṣaájú ilé-iṣẹ́ náà bí i ilé ni fún àwọn akọrin bí i korede bello dr sid d'prince di' ja johnny drille ladipoe dna twins rema arya starr magixx boy spyce a tún ma rí àwọn agbórinjáde bí i jazzy fúnra rẹ̀ altims àti baby fresh ní 2014 dj big n jẹ́ dj àkọ́kọ́ tí ile-iṣẹ́ náà ní tiwa savage wande coal reekado banks àti iyanya ni wọ́n ti wà ní ilé-iṣẹ́ náà rí gẹ́gẹ́ bí i olórin ní 8th may 2012 ilé-iṣẹ́ náà ṣe àgbéjáde àtòjọ awo-orin solar plexus ní january 2019 kupanda holdings tí ń ṣe ẹ̀ka kupanda capital àti tpg growth bá ilé-iṣẹ́ mavin dòwò pọ̀ pẹ̀lú iye owó tí ó ń lọ mílíọ́ọ̀nù dollar àtòjọ àwọn àmì-ẹ̀yẹ wọ́n yan mavin records gẹ́gẹ́ bí i ilé-iṣẹ́ agbórinjáde tó dára jù lọ ní ọdún 2013 lábẹ city people entertainment awards wọ́n sí tún gba àmì-ẹ̀yẹ ní ọdún 2014 lọ́wọ́ city people entertainment awards
reminisce reminisce alaga ibile jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ ajilete ìbílẹ̀ gúúsù yewa ní ìpínlẹ̀ ogun apá ìwọ̀ oòrùn orílẹ̀-èdè nàìjíríà wọ́n bí i ní ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n oṣù ṣẹẹrẹ ọdún 1981 ní ìpínlẹ̀ kaduna apá àríwá orílẹ̀-èdè nàìjíríànigerian rapper singer and songwritera bí rẹ̀mílẹ́kún khàlid sàfárù ní ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n oṣù ṣẹẹrẹ orúkọ mìíràn tí arákùnrin yìí ń jẹ́ ni orí-ìtàgé ni reminisce àti alága ìbílẹ̀ ó jẹ́ olórin tàka-súfèé ti ilè nàìjíríà bẹ́ẹ̀ náà ni ó jẹ́ òǹkọrin àti eléré tíátà láti ìpínlẹ̀ ògùn ògbóǹtarìgì ni ó jẹ́ nínú fífí èdè gèésì àti èdè abínibí rẹ̀ yorùbá dánilárayá ìfáàrà reminisce alaga ibile jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ ajilete ìbílẹ̀ gúúsù yewa ní ìpínlẹ̀ ogun apá ìwọ̀ oòrùn orílẹ̀-èdè nàìjíríà wọ́n bí i ní ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n oṣù ṣẹẹrẹ ọdún 1981 ní ìpínlẹ̀ kaduna apá àríwá orílẹ̀-èdè nàìjíríà nígbà tí ó wà ní ilé ìwé oríṣiríṣi àwọn orin tàka-súfèé tí orílè-èdè nàìjíríà àti ti òkè-òkun ni ó máá ń gbọ́ ó sì máa ń kọ àwọn orin yìí ní orí-ìtàgé nígbàkugbà tí ilé-ìwé rẹ̀ bá ń ṣe síse ó mú ìdàgbàsókè bá ẹ̀bùn orin kíkọ rẹ̀ nípa gbígbọ́ orin àwọn olórin tàka-súfèé mìíràn bí i nas jay z àti snoop dogg ilé- ẹ̀kọ́ gíga pólì ni ó ti ka kárà-kátà purchasing and supply iṣẹ́ nínú orin kíkọ ọdún 2006 ní ó se àkójọ àwọ rẹ̀ àkọ́kọ́ ní ilé-iṣẹ́ coded tunes àmọ́ àwo yìí kò jáde fún ìdí èyí ó gbájúmọ́ ẹ̀kọ́ àtí píparí ẹ̀kọ́ rẹ̀ ní ọdún 2008 ó padà sí ori kíkọ lára àwọn orin tí ó sọ ọ́ di ìlú mọ̀ọ́ká ni bachelor's life tí ó kọ pẹ̀lú 9ice àti if only tí dtunez gbé jáde ilé-iṣẹ́ edge records gbà á láti máa ṣiṣẹ́ fún wọn bẹ́ẹ̀ náà ni ó jẹ́ olùdásílẹ̀ àti olùdaeí ilé-iṣẹ́ lrr records ní ọdún 2014 time magazine pe reminisce ní ọ̀kan nínú àwọn olórin tàka-súfèé méje tí o gbọ́dọ̀ rí “one of the seven world rappers you should meet” ọ̀kan lára àwọn ayélujára fún orin pè é ni notjustok gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan nínú àwọn olórin tàka-súfèé mẹ́ta tí ó mú òkè ní ọdún 2014 àwo rẹ̀ tí àkọ́lé rẹ̀ jẹ́ local rappers tí ó gbé jáde ní ọdún 2015 èyí tí ó kọ pèlú olamide àti phyno mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àrínyàngiyàn dání pé àwọn tí wọ́n fi èdè gẹ̀ẹ́sì kọrin ní ó báwí bí i mi àti mode9
zlatan ọmọ́níyì tèmídayọ̀ raphael bí ní ọjọ́ kọnkọ̀dínlógún oṣù kejìlá ọdún 1994 tí wọ́n mọ̀ ọ́ ní tiyì sí zlatan ìbílẹ̀ jẹ́ rápà akọrin akọ-orin olórin àti oníjó nàìjíríà láti èkìtì ijero local government area ìpínlẹ̀ èkìtì ó jẹ́ olórí àti olùdásílẹ̀ zanku records ní ọdún 2014 ó gba ipò àkọ́kọ́ tí ilé-iṣẹ́ airtel pàsè tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ one mic talent show tí wọ́n ṣe ní ọdún 2014 abéòkúta ìpínlẹ̀ ògùn kó tó di ìparí ọdún 2018 zlatan kọ orin sílẹ̀ tí ó pè ní zanku pẹ̀lú ijọ́ tuntun tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ orúkọ orin náà ní ọjọ́ kẹ́ta oṣù kọkọ̀nlá ọdún 2019ó fi álíbọ̀bù àkọ́kọ́ rẹ̀ sílẹ̀ tí orúkọ rẹ̀ jẹ́ zanku tí ó túmọ̀ sí zlatan abeg no kill us akọrin náà sọ wí pé ó wu òun láti di agbábọ̀lù-afẹṣẹ̀gbá ní ọdún 2020 pé kí í ṣe olórin ọmọ́níyì tèmídayọ̀ raphael bí ní ọjọ́ kọnkọ̀dínlógún oṣù kejìlá ọdún 1994 tí wọ́n mọ̀ ọ́ ní tiyì sí zlatan ìbílẹ̀ jẹ́ rápà akọrin akọ-orin olórin àti oníjó nàìjíríà láti èkìtì ijero local government area ìpínlẹ̀ èkìtì ó jẹ́ olórí àti olùdásílẹ̀ zanku records ní ọdún 2014 ó gba ipò àkọ́kọ́ tí ilé-iṣẹ́ airtel pàsè tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ one mic talent show tí wọ́n ṣe ní ọdún 2014 abéòkúta ìpínlẹ̀ ògùn kó tó di ìparí ọdún 2018 zlatan kọ orin sílẹ̀ tí ó pè ní zanku pẹ̀lú ijọ́ tuntun tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ orúkọ orin náà ní ọjọ́ kẹ́ta oṣù kọkọ̀nlá ọdún 2019ó fi álíbọ̀bù àkọ́kọ́ rẹ̀ sílẹ̀ tí orúkọ rẹ̀ jẹ́ zanku tí ó túmọ̀ sí zlatan abeg no kill us akọrin náà sọ wí pé ó wu òun láti di agbábọ̀lù-afẹṣẹ̀gbá ní ọdún 2020 pé kò kí í ṣe olórin ìbẹ̀ẹ̀rẹ ayé àti ìgbé ayé rẹ̀ ọmóníyì tèmídayọ̀ raphael jẹ́ bíbí àti dàgbà ní ìlọrin ìpínlẹ̀ kwara ṣùgbọ́n ó ní ìbátan pẹ̀lú ìpínlẹ̀ èkìtì ní ọdún 2011 ó jáde pẹ̀lú ìmọ̀ ètò ìṣòwò ní moshood abíọ́lá politẹ́nííkì zlatan pinnu láti mú orin kíkọ ní iṣẹ́-ààjò rẹ̀ lẹ́yìn tó parí ilé-ìwé sẹ́kọ́ndírì ní ìgbà tí ó pé ọmọ ọdún mọkàndínlógún ó gba ipò kìíní ní ìdíje tí airtel pàsè èyí tí wọ́n ṣe ní ọdún 2014 one mic campus tour ìdíje olórin tí wọ́n ṣe ní abẹ́òkúta ìpínlẹ̀ ògùn ó di ìlú mọ̀ ọ́ ká láàárín ẹgbé akọrin nàìjíríà lẹ́yìn tí ó fí orin tí ọlámìídé ràn ọ́ lọ́wọ́ nínu ẹ̀my body ní ọdún 2017 ní ọdún 2018 lawrence irabor ìkan lára àwọn tó ni alleluyah boiz entertainment fọwọ́ bọ ìwé pẹ̀lú zlatan sí láàárín wọn abe record nígbà tó gbó orin tí zlatan kọ pẹ̀lú ọlámìídé ó wá sọ wí pé ‘i don’t regret signing zlatan t o abe records’
kcee kingsley chinweike okonkwo tí a mọ̀ sí kcee jẹ́ olórin nàìjíríà àti ẹni tí ó máa ń kọ orin ó ti fìgbà kan wà nínú ẹgbẹ́ orin hip hop tí wọ́n ń pè ní kc presh ó wá láti ìlú ní uli ní ìjọba ìbílẹ̀ ihiala ní ìpínlẹ̀ anambra nàìjíríà ní báyìí ó ní àdéhùn iṣẹ́ pẹ̀lú five star music ó ṣiṣẹ́ pẹ̀lú del b olùgbéjáde rẹ́kọ́ọ̀dù tí ó gbajúgbajà fún gbígbé orin limpopo jáde òun ni ẹ̀gbọ́n e-money ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ìgbé-ayé àti iṣẹ́ orin kcee àti ìkejì rẹ̀ tí wọ́n jọ ń kọrin tí ó sì tún jẹ́ ọ̀rẹ́ rẹ̀ hajie jọ ń kọrin papọ̀ fún ọdún méjìlá wọ́n pàdé nínú ẹgbẹ́ akọrin ìjọ wọ́n jọ wà nínú ẹgbẹ́ akọrin papọ̀ títí tí wọ́n fi lọ fún ìdíje ètò ojú-ayé star quest lórí tv tí àwọn méjèèjì sì gbégbá oróókè lórí ètò náà àwọn iṣẹ́ wọn papọ̀ gẹ́gẹ́ bí i ẹgbẹ́ olórin fún wọn ní òkìkí díẹ̀ di ọdún 2011 tí wọ́n pínyà tí oníkálukú sì bẹ̀rẹ̀ sí í lé iṣẹ́ orin rẹ̀ lọ́tọ́ọ̀tọ̀ kcee kọ sweet mary j tí ó jẹ́ orin àdákọ rẹ àkọ́kọ́ ní ọdún 2020
kizz daniel oluwatobiloba daniel anidugbe tí àwọn ènìyàn tún mọ̀ sí orúkọ ìtàgé rẹ̀ kizz daniel jẹ́ nàìjíríà olórin àti a-kọ-orin ó gbajúgbajà fún àwọn orin rẹ̀ woju and yeba orúkọ ìtàgé kiss daniel ni ó ń jẹ́ tẹ́lẹ̀ kí ó tó yí i dà ní oṣù karùn-ún ọdún 2018 ó bọwọ́lùwé àdéhùn iṣẹ́ pẹ̀lú g-worldwide entertainment ní ọdún 2013 ṣùgbọ́n ó fi ilé-iṣẹ́ orin náà sílẹ̀ lẹ́yìn ìjà lórí àdéhùn tí kì í ṣe gbòńkẹ́lẹ́ àti ìgbẹ́jọ́ nílé ẹjọ́ ó dá ilé-iṣẹ́ orin fly boy inc record label sílẹ̀ ní oṣù kọkànlá ọdún 2017 ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ìgbésí-ayé wọ́n bí kizz daniel gẹ́gẹ́ bí i olúwatóbilọ́ba daniel anidugbe ní abẹ́òkúta ìpínlẹ̀ ògùn nàìjíríà ó jẹ́ ọmọ ìjọba ìbílẹ̀ abeokuta north ẹ̀kọ́ ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ girama abeokuta grammar school ó sì kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní federal university of agriculture abeokuta ní ọdún 2013 pẹ̀lú ìwé ẹ̀rí ní water resources management and agrometeorology ní ìgbà tí ó ṣì wà ní yunifásítì ó pinnu láti máa lé iṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú ẹ̀kọ́ rẹ̀ papọ̀ ìgbé ayé rẹ̀ ní ọjọ́ kìíní oṣù karùn-ún ọdún 2021 ó bí àwọn ìbẹẹ̀ta jamal jalil àti jelani pẹ̀lú ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ tí ẹnikẹ́ni kò mọ̀ kizz sọ lẹ́yìn ìgbà díẹ̀ bí ó ṣe pàdánù ọ̀kan nínú àwọn ìbẹẹ̀ta rẹ̀ jamal ní ọjọ́ mẹ́rin lẹ́yìn ọjọ́ tí ó bí wọn bí ó ṣe ra ilé oníyàrá méjì kọ̀ọ̀kan fún jalil àti jelani iṣẹ́ ní oṣù karùn-ún ọdún 2015 kizz daniel láfarabara fi orin kẹta léde tí ó pe àkọ́lé rẹ̀ ní “laye” ní ọjọ́ tí ó jẹ́ ọjọ́ ìbí rẹ̀ pẹ̀lú fọ́nrán tí aje films darí tí wọ́n yà ní oríṣìíríṣìí ibi ní ìlà-oòrùn áfíríkà lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjì tí orin náà jáde daniel fi àwo orin rẹ̀ kìíní tí ó pe àkọ́lé rẹ̀ ní new era léde ní ọjọ́ kẹrìnlá oṣù karùn-ún ọdún 2016 lẹ́yìn tí ó fi ilé iṣẹ́ orin tí ó ń bá ṣiṣẹ́ tẹ́lẹ̀ sílẹ̀ g-worldwide ó lọ dá tirẹ̀ sílẹ̀ flyboy inc tí ó sì gba àwọn olórin tuntun méjì wọlé láìpẹ́ yìí demmie vee àti philkeyz lẹ́yìn èyí ni kizz daniel kọ nínú orin demmie vee single tí wọ́n pè ní you go wait 2018 jẹ́ ọdún tí ó da fún olórin tí ó kọ woju ó pe wizkid sí orin tí ó gbalégbako for you àti davido sí orin mìíràn one ticket tí ó gún òkè lorí àtẹ láàárín wákàtí mẹ́rìnlélógún tí wọ́n fi léde ní ọjọ́ ọgbọ̀n oṣù kejìlá ọdún 2018 kizz daniel fi àwo-orin rẹ̀ kejì léde èyí tí ó jẹ́ èkíní rẹ̀ lábẹ́ ilé-iṣẹ́ orin flyboy inc tí wọ́n pe àkọ́lé rẹ̀ ní no bad songz àwo-orin náà ní orin ogún nínú pẹ̀lú èyí tí ó fi fi léde tẹ́lẹ̀ one ticket tí ó kọ pẹ̀lú davido àwọn olórin mìíràn tí ó kọrin pẹ̀lú nínú àwo-orin náà ni nasty c diamond platiumz philkeyz demmie vee dj xclusive wretch 32 diplo àti sarkodie àwo-orin yìí gba ọ̀pọ̀lọpọ̀ ì-gbóríyìn-fún lọ́dọ̀ àwọn olólùfẹ́ orin ó gba ipò 55 ní orí us itunes chart ó sì gba ipò kìíní lórí àtẹ̀ àwo-orin lágbàáyé láàárín wákàtí mẹ́rìnlélógún tí wọ́n fi léde ní ọjọ́ karùndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹfà ọdún ó fi àwo-orin rẹ̀ kẹta 'king of love'léde ní 2017 ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ ni wọ́n rò pé ó máa pàrọ̀ iṣẹ́ sí iṣẹ́ adẹ́rìn-ín-pòṣónú nítorí pé ó ń fi àwọn fọ́nrán apanilẹ́rìn-ín léde ṣùgbọ́n ṣá ó sọ pé òun ò ní èrò láti pàrọ̀ iṣẹ́ sí iṣẹ́ adẹ́rìn-ín-pòṣónú nítorí iṣẹ́ orin gan-an ni ẹ̀bùn òun ìjà ilé-iṣẹ́ orin àti orúkọ yíyídà ní oṣù kọkànlá 2017 kizz daniel kéde ìpínyà rẹ̀ kúrò lábẹ́ ilé-iṣẹ́ orin g-worldwide ó sì dá ilé-iṣẹ́ orin tirẹ̀ sílẹ̀ tí ó pe ní flyboy inc àwọn ilé-iṣẹ́ orin ti tẹ́lẹ̀ gbé e lọ ilé-ẹjọ́ ṣùgbọ́n kò jẹ̀bi ọ̀kankan nínú ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án ní oṣù karùn-ún 2018 kizz daniel kéde pé òun ti yí orúkọ ìtàgé òun kúrò láti kiss daniel sí kizz daniel orúkọ èyí tí ó farahàn lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ ní orí àwọn ẹ̀rọ ìbánidọ̀ọ̀rẹ́ rẹ̀ spotify tuntun àti apple music accounts di ṣíṣí lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ pẹ̀lú orúkọ kizz daniel àti àwọn orin rẹ̀ tuntun ní oṣù kẹfà 2018 ilé-iṣẹ́ orin ti tẹ́lẹ̀ tí kizz daniel wà lábẹ́ wọn g-worldwide gbìyànjú láti ní àṣẹ sí orúkọ “kizz daniel” wọ́n sì tún gba olórin yìí níyànjú láti dẹ́kun lílo orúkọ yìí àbí kí ó fojú winá òfin nínú àtẹ̀jáde ìròyìn tí wọ́n fi ṣọwọ́ sí àwọn ilé ìròyìn ní oṣù kẹwàá 2018 daniel fèsì sí ìwé ìpẹ̀jọ́ àti ọ̀rọ̀ àwọn ilé-iṣẹ́ g-worldwide láti ẹnu agbẹjẹ́rò tirẹ̀
lil kesh kẹ́ṣhiró ọlọ́ládẹ́ bí ní oṣù kẹ́ta ọjọ́ kẹtàdínlógún ọdún 1995 tí àwọn ènìyàn mọ sí lil kesh jẹ́ olórin rápà àti akọ-orin nàìjíríà ó di ìlú-mọ̀-ọ́-ká lẹ́yìn tó kọ orin shoki ìbẹ̀rẹ̀ ayé rẹ̀ kẹ́shinró ọlọ́láde jẹ́ bíbí àti dàgbà sí bàrígà agbègbè kan ní ìpínlẹ̀ èkó ní nàìjíríà ẹ̀kọ́ rẹ̀ ó lọ sí stockbridge college fún ẹ̀kọ́ pámárìlì àti ṣẹ́kọ́ndàrì lẹ́yìn náà ó lọ sí fáṣítì èkó níbi tó tí kọ́ ẹ̀kọ́ ìmọ̀-ẹ̀dá-èdè lẹ́yìn náà ó lọ sí national open university nàìjíríà níbi tó ti kọ́ ẹ̀kọ́ mass communication lórí íńtánẹ́ẹ̀tì ìṣe ààjò ó bẹ̀rẹ̀ orin kíkọ gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́-ààjò rẹ̀ ní ọdún 2012 nígbà tó ń rápà láàárín àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ ní bàrígà lẹ́yìn ìgbà díẹ̀ ó kọ orin àkọ́kọ́ rẹ̀ lyrically orin àkọ́kọ́ rẹ̀ yìí gbajúmọ̀ láàárín àwọn fáṣítì nàìjíríà àbábọ̀ rẹ̀ jẹ́ kí lil kesh tọwọbọ̀wẹ́ pẹ̀lú yahoo boy no laptop nation tí àwọn ènìyàn mọ̀ sí ybnl nation ybnl tó jẹ́ ilé-iṣẹ́ olórin aládàání tí olùdálè rẹ̀ jẹ́ ọlámìídé adédèjì ní ọdún 2012 lábẹ́ ybnl ó kọ shoki efejoku gbèsè àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ ó fi álíbọ̀mù àkọ́kọ́ rẹ̀ náà lẹ̀ tí ó jẹ' yagi
living in bondage 1992 nigerian filmliving in bondage gbígbé nínú ìgbèkùn apá kìn-ín-ní àti apá kejì jẹ́ eré àgbéléwò asaragágá orílẹ èdè nàìjíríà tí chris obi rapu jẹ́ olùdarí rẹ̀ a sì ti ọwọ́ kenneth nnebue àti okechukwu ogunjiofor kọ ọ́ aṣagbátẹrù erè yìí ni ogunjiofor jafac wine ló ṣe onígbọ̀wọ́ eré náà lára àwọn akópa inú eré-oníṣe àgbéléwò yìí ni kenneth okonkwo àti nnenna nwabueze nínú ẹ̀dá-ìtàn àlàjá wọn ó jẹ́ eré-oníṣe àgbéléwò orílẹ -èdè nàìjíríà àkọ́kọ́ tí ó dé ipile àṣeyọrí tó ní iyì nínú ní oṣù kẹjọ ní ọdún 2015charles okpaleke gba ẹ̀tọ́ lórí living in bondage fún àkókò ọdún mẹ́wàá lábé ìṣàkóso ilé-isẹ́ ìsagbátẹrù play entertainment network ní oṣù kọkànlá ọdún 2019 a fi eré-oníṣe àgbéléwò ṣíṣẹ̀-n-tẹ̀lẹ́ tí gbogbo tí tomodé-tàgbá tí ń ṣàfẹ́rí living in bondage breaking free hàn fún ìgbà àkọ́kọ́ ni ìlú eko ìtàn eré andy okeke kenneth okonkwo àti ìyàwó rẹ̀ merit nnenna nwabueze bá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìjákunlẹ̀ pàdé bí ìṣe ṣe ń bọ́ lọ́wọ́ wọn ni wọ́n tún yan ara wọn jẹ nípa ṣíṣe àgbèrè wọn pàdánù owó ìfipamọ́ wọn nínú ìdókòwó ńlá àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọkùnrin wọ̀bìà àti onífẹ̀ẹ́-kú-fẹ̀ẹ́ ló máa kọnu ìfẹ́ sí merit pàápàá jù lọ àwọn ọ̀gá rẹ̀ ichie million francis agu àti chief omego kanayo o kanayo ní ọ̀pọ̀ ìgbà andy máa ń sábà ṣe àfiwéra àìlóríre ti rẹ̀ pẹ̀lú àṣeyọrí àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀ pàápàá paul okechukwu ogunjiofor tí ó jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́-tímọ́ rẹ̀ pẹ̀lú gbogbo àtìlẹ́yìn àti sùúrù tí merit ní andy ń wá gbogbo ọ̀nà láti dí olówó pẹ̀lú ohunkóhun àti ọ̀nàkọnà tí ó bá fẹ́ gbà pọ́ọ̀lù ọlọ́gbọ́n àrékérekè tú àṣírí rẹ̀ - ẹgbẹ́ òkùnkùn tí gbogbo ọmọ ẹgbẹ́ máa ń dá májẹ̀mú ìsòótọ́ àti ìdúróṣinṣin pẹ̀lú lucifer tí wọ́n sì tún máa ń pá àwọn tí wọ́n fẹ́ràn gẹ́gẹ́ bí ohun ètùtù láti rí ọrọ̀ àti owó jaburata láì fi àkókò ṣòfò andy gbà láti fi ìyàwó rẹ̀ merit ṣe ìrúbọ ètùtù merit kú sí ilé ìwòsàn lẹ́yìn ọjọ́ tí wọ́n ṣe ètùtù kí ó tó kú ó fi ọkọ rẹ̀ ré ọrọ̀ pàjáwìrì àti ìgbéyàwó ẹlẹ́kejì tí andy ní fa àkíyèsí àwọn àna rẹ̀ àná èyí tí ó mú kí wọ́n fi ẹ̀sùn pípa ọmọ wọn merit kàn án ó bẹ̀rẹ̀ sí ní àwọn ìdojúkọ- bí àwọn ayàwòrán gbajúmò ṣe máa ń dá sí ìgbé sí ayé ojoojúmọ́ rẹ̀ ìyàwó tuntun rẹ̀ ego ngozi nwosu gbé owó rẹ̀ sàlo lẹ́yìn ìgbéyàwó wọn àti bí ẹ̀mí òkú merit ṣé ń lé e kiri tí ó ṣì ń seru bà á ní àwọn ìgbà tí kò lérò andy tẹ̀síwájú láti máa bá chinyere jennifer okere gbé gẹ́gẹ́ bí ìyàwó obìnrin míràn tí ọ̀rẹ́ merit caro ngozi nwaneto mú u pàdé chinyere kú ikú àìtọ́jọ́ lẹ́yìn ìgbà tí caro fún ní májèlé jẹ lẹ́yìn èyí caro gbìyànjú láti sá lọ sí òkè òkun pẹ̀lú owó tí chinyere jí lọ́wọ́ ọkọ rẹ̀ caro kú nígbà tí ó ń lọ sí ilé ọkọ̀-òfuurufú lẹ́yìn ìgbà tí awakọ̀ kán gba lóju títì àwọn apànìyàn pa paul lẹ́yìn tí andy dalẹ́bi fún ìdí tí ó fi wọ́ inú ẹgbẹ́ òkùnkùn lẹ́yìn gbogbo èyí andy padà lọ bèrè ìrànwọ́ nínú ẹgbẹ́ òkùnkùn náà ṣùgbọ́n olúwo ẹgbẹ́ náà ní dandan ni ki ó pẹ̀rọ̀ fún òkú ìyàwó nípa gígé nǹkan ọmọ ọkùnrin rẹ̀ àti fífọ́ ara rẹ lójú ó kọ̀ ó sì di erè tí ó ń gbé lábẹ́ afárá di ìgbà tí tina rita nzelu- ẹni tí ó ń ṣe iṣẹ́ aṣẹ́wó tẹ́lẹ̀ nígbà tí andy kọ́kọ́ pàdé rẹ̀ tí ó mú lọ sí ẹgbẹ́ òkùnkùn wọn gẹ́gẹ́ bí ohun èlò ètùtù kí àṣírí rẹ̀ tó tú mú u lọ sí ilé-ìjọsìn níbi tí andy tí jẹ́wọ́ wí pé òun lòún pá merit ìyá andy grace ayozie sunkún létí ibojì ìyàwó ọmọ rẹ̀ ó sì tọrọ ìdáríjì ní ìgbẹ̀yìn eré andy tí gba ìwòsàn ó sì ń jọ́sìn pẹ̀lú àwọn ajíhìnrere onígbàgbó tí wọ́n dáa lójú wí pé ó ti gba ìdáríjì fún gbogbo ẹ̀sẹ̀ rẹ̀ albètẹ́lẹ̀ ní ọdún 2015 àwọn àgbà òṣèré ramsey nouah àti charles okpaleke gba ẹ̀tọ́ lórí living in bondage láti ọwọ́ kenneth nnebue àtúnṣe eré náà ni ilẹ̀ europe america àti nàìjíríà ìròyìn jáde lórí instagram ṣùgbọ́n ipele ìdàgbàsókè ló wà fún àkókò ọdún mẹ́ta ní 2018 nouah ṣe ìkéde pé àtúnṣe eré náà yóò wáyé ní ṣíṣẹ̀-n-tẹ̀lẹ́ èyí tí a pe àkọlé rẹ̀ ní living in bondage breaking free èyí tí ó jáde ní november 8 2019 nouah tí ó ṣe olúwo tuntun ṣé ìfarahàn àkọ́kọ́ gẹ́gẹ́ bíi olùdarí eré náà pẹ̀lú àwọn òṣèré míràn tí wọ́n kópa nínú eré náà nígbà àkọ́kọ́ tí a gbé e jáde bíi okonkwo udokwu àti kanayo ìtàn èyí dá lórí ọmọ andy nnamdi àti bí ó ṣe fi ìwà burúkú jọ bàbà rẹ̀ mbgn àná muna abii ṣé ìfarahàn àkọ́kọ́ gẹ́gẹ́ bí osere pẹ̀lú swanky jka tí ó ṣe ìpadàbọ̀ gẹ́gẹ́ bí òṣèré nínú eré yìí ní oṣù karùn-ún ọdún 2020 á gbé fíìmù àgbéléwò yìí sórí netflix
sonia manzano sonia manzano june 12 1950 je osere ara amerika