raw_text
stringlengths 2
128k
|
---|
omo-love branch nigerian footballer omo-love branch tí wọ́n bí lọ́jọ́ kẹwàá oṣù kìíní ọdún 1974 jẹ́ agbábọ́ọ̀lù-àfẹsẹ̀gbá bìnrin ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà tí ó máa ń gbá bọ́ọ̀lù ní àyè àbò-ilé fún ọkọ̀ agbábọ́ọ̀lù-àfẹsẹ̀gbá obìnrin nigeria ó wà lára ikọ̀ àkọ́kọ́ àwọn obìnrin tí wọ́n ṣojú nàìjíríà nínú ìdíje 1991 fifa women's world cup àti 1995 fifa women's world cup
|
hafsat abiola nigerian human rights civil rights and democracy activist hafsat olaronke abiola-costello tí wọ́n bí ní ọjọ́ ọkàn lé lógún oṣù kéje ọdún 1974 ní ìlú èkó ó jẹ́ àjàfẹ́tọ̀ọ́ ẹ̀tọ́ ọmọ nàìjíríà àwọn ẹ̀tọ́ aráàlú àjàfẹ́tọ̀ọ́ ìjọba ara wa àti olùdásílẹ̀ kudirat initiative for democracy kind èyí tí ó ń wá láti fún àwùjọ aráàlú lágbára àti ìgbélárugẹ ìjọba tiwa-n-tiwa ní ilẹ̀ nàìjíríà ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ àti ètò ẹ̀kọ́ abiola-costello ni ọmọ kẹjọ ti ààrẹ tí wọ́n yan ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà tí kò jẹ́ olóyè moshood abíọ́lá àti olóògbé kudirat abíọ́lá bàbá rẹ̀ moshood abíọ́lá tí wọ́n fi sẹ̀wọ̀n l'ọ́wọ aṣẹ̀jọba gen sani abacha fún ìwà ọdaràn lẹ́yìn tí ó ti kéde ara rẹ̀ ní ààrẹ àgbà abíọ́lá kú nígbà tí ó wà ní àtìmọ́lé ní ọdún 1998 láàkókò tí wọ́n pa ìyá rẹ̀ ní àkókò ìfihàn kan fún ìtúsílẹ̀ ọkọ rẹ̀ ní ọdún 1996 ní oṣù kẹfà ọdún 2018 ààrẹ muhammadu buhari fún un ní olórí aláàkóso fún bàbá rẹ̀ tó kú olóyè moshood abíólá fún ẹni tí ó yẹ kó jáwé olúborí nínú ìdìbò ààrẹ ní ọjọ́ kejìlá oṣù kẹfà ọdún 1993 gcfr abiola-costello lọ ilé-ìwé gíga rẹ̀ ní queens college yaba ìlú èkó ó kàwé gboyè ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga phillips academy andover ní ọdún 1992 àti harvard college ní ọdún 1996 níbití ó ti gba oyè kan ní ètò-ọ̀rọ̀ ìdàgbàsókè development economics àti lẹ́hìn náà gba msc ní international development láti tsinghua university beijing
|
abiola dosunmu oloye abiola dosunmu ti a mo tele si dosunmu-elegbede-fernandez a bi ni july 29 1947 je onisowo ni orile ede naijiria o je alafeati o nise ibile ni afikuno di erelu kuti eekerin ti ilu eko
|
jessica oyelowo jessica oyelowo née watson ti a bi ni 1978 je osere ati okorin ti britain iberepepe aye oruko ti won so ni jessica watson ni ipswich o si dagba si suffolk ni england o losi ile iwe alakobere ti woodbridge school nigba ti o wa ni kekere o si je omo egbe national youth music theatre ise ni odun 2006 oun lo se detective sergeant alex jones ni mayo o si tun wa ninu ere ti won pe ni murphy's law ti james nesbitt na wa nibe in 2007 o fi ohun re sile lati se mrs equiano ti oko mr equiano naa re si je husband olaudah equiano ninu ere grace unshackled the olaudah equiano story eyi ti o je ere itage ti o maa n waye lori ti won yalo lati equiano's 1789 autobiography ti a mo si ti akoko iru re si waye lori bbc 7 ni osu kerin odun 2007 igbe aye oyelowo n gbe ni tarzana ni ni pelu oko re ti oun naa je osere ti oruko re si n je awon meejeji pade nigba ti won lo si won ni awon omo merin ti won n gbe ni england awon meejeji si je kiteeni oyelowo ati oko re je naturalised us citizens ni 20 july 2016 gege bi o ti je aya omo yi ti o tun je omooba oyelowo ni eto si ki a pe ni amo kii saba lo
|
tanimowo ogunlesi nigerian activist tanimowo ogunlesi 1908-2002 jẹ́ ajàfẹ́ẹ̀tọ́ àwọn obìnrin ilẹ̀ nàìjíríà ó tún jẹ́ adarí women's improvement league ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn adarí tó ń já à fún ẹ̀tọ́ àwọn obìnrin àti ọ̀kan lára àwọn olùdásílẹ̀ national council of women societies tí ń ṣe aṣáájú iléeṣẹ́ ajàfẹ́ẹ̀tọ́ àwọn obìnrin ti nàìjíríà ìgbésí ayé rẹ̀ tanimowo ogunlesi lọ iléèkọ́ kudeti girls school ibandan ó tún kàwé ní iléèkọ́ united missionary college umc fún ìkàwágboyè ìkẹ́ẹ̀kọ́ gẹ́gẹ́ bí i olùkọ́ ó jẹ́ ẹni àkọ́kọ́ láti ṣe ìdásílẹ̀ ilé-ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ oníléégbèé ní ìlú ìbádàn children home school ó jẹ́ ààrẹ àkọ́kọ́ ti national council of women societies ní ọdún1959 ó ṣiṣẹ́ ribiribi lórí ẹ̀tọ́ àwọn obìnrin láti ma dìbò àti láti ní àǹfààní sí àwọn ohun-èlò ẹ̀kọ́ ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí i ọ̀pọ̀ àwọn adarí obìnrin ìgbà ayé rẹ̀ kò ní ẹjọ́ tó tako sí àwọn ọkùnrin gẹ́gẹ́ olórí àwọn ìdílé oríléèdè ilẹ̀ nàìjíríà
|
kemi omololu-olunloyo nigerian journalist and activistkemi omololu-olunloyo olukemi omololu-olunloyo tí a bí ní ọjọ́ kẹfà osù kẹjọ1964 jè akọ̀ròyìn ajàfẹ́tọ̀ọ́ọmọnìyàn àti gbajúmọ̀ lórí ìkànnì ayélujára ní nàìjíríà ó jẹ́ gbajúmọ̀ ní orí ìkànnì ayélujára ní nàìjírìà pàápàá jùlọ fún síse àríyànjiyàn lóri àwọn ọ̀rọ̀ tí ó múni lókàn bi ìfẹ̀ónú hàn ti end sars ní ọdún 2020 àti ikú akẹ́kọ̀ọ́ ilé ẹ̀kọ́ àdáni kan ní èkó omololu-olunloyo ti dojúkọ àfisùn orísii nípa ayé àti isẹ́ rẹ̀ tí púpọ̀ rẹ̀ ò sì jẹ́ òtítọ́
|
faith abiola oyedepo faith abiola oyedepo born febuary 5 1958 is a nigerian preacher she is the wife of david olaniyi oyedepo who is a christian author businessman architect the founder and presiding bishop of living faith church worldwide and also the chancellor of covenant university and landmark university respectivelyfaith abiola oyedepo is the co founder of faith academy secodary schoolshe is also a christian authorshe was blessed with four childrendavidisaaclove and joyce
|
alimotu pelewura oloye alimotu pelewura 18651951 jẹ onísòwò naijiria kàn tó jẹ adarí ẹgbẹ awon obinrin ti oja eko egbé agbawi obìnrin tí o jẹ onísòwò ní eko o tún jẹ ẹlẹgbẹ òṣèlú pàtàkì ti herbert macaulay ìgbésí ayé ìbẹ̀rẹ̀ ìlú eko ní wón tí bí pelewura si idile nla kan ó jẹ́ àgbà ti àwọn ọmọ méjì tí ìyá rẹ̀ bí ìya rẹ jẹ oníṣòwò ẹja àti pelewura tún yan ìṣòwò ẹja gégébí iṣẹ ní ọdún 1900 o tí di aṣáájú àwọn obìnrin àti onísòwò ọjà pàtàkì àti ní ọdún 1910 oba eshugbayi eleko fún ní oye olori ní awọn ọdun 1920 o jẹ aṣaaju ọjà ẹran ereko pẹlu atilẹyin herbert macaulay o dìde láti di olórí ẹgbẹ tuntun tí àwọn obìnrin tí ọjà eko ó jẹ́ ọmọ ẹ̀yà awori ti yorùbá
|
charlotte obasa charlotte olajumoke ọbasá tí orúkọ ìbí rẹ̀ ń jẹ́ blaize ọjọ́ keje oṣù kìíní ọdún 1874 sí ọjọ́ ẹ̀tà lè lógún oṣù kẹwàá ọdún 1953 jẹ́ ẹni àrà ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà àti onínúureó jẹ́ ọmọbìnrin oníṣòwò rb blaize àti ìyàwó oníṣègùn orisadipe obasa ayé rẹ̀ sàró obasá kan ni wọ́n bí gẹ́gẹ́ bí i ọ̀kan lára àwọn ọmọ richard beale blaize ọlọ́rọ̀ àti ọlọ́jà olóṣèlú àti ìyàwó rẹ̀ emily cole blaize ó lo àwọn ọdún ìgbékalẹ̀ rẹ̀ ní ìlú èkó níbití bàbá rẹ̀ ti ṣe àtẹ̀jáde àwọn ìwé ìròyìn ti orílẹ-èdè the lagos times ati gold coast colony advertiser àti the lagos weekly times ó ka ẹ̀kọ́ dáradára àkọ́kọ́ ni ilé-ìwé ti àwọn ọmọbìnrin anglican lónìí ní ìlú èkó lẹ́hìn náà ní ilé-ẹ̀kọ́ kan ní england ní ọdún 1902 ó ṣe ìgbéyàwó sí ọmọ ọba sàró prince orisadipe obasa bàbá rẹ̀ fún tọkọtaya ní ilé titun kan gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bùn ìgbéyàwó nígbẹ̀yìn náà ni wọ́n wá ń pè é ní ilé babafunmi obasa àti ọkọ rẹ̀ tẹ̀síwájú láti bí ọmọ márùn ùn papọ̀ ẹ̀gbọ́n sí kofo lady ademola obasa jẹ́ òǹtajà àti onínúure tí ó ṣe àgbéga ètò àwọn obìnrin àti ẹ̀kọ́ ní ọdún 1907 ilé-ìwé àwọn ọmọbìnrin ti èkó tí wọ́n wá ń pè ní wesleyan girls high school tí ṣíṣí rẹ̀ wá nípasẹ̀ ìgbìyànjú rẹ̀ ní fífún ohun-ìní kan tí ó yá ilé-ìwé náà ní ọdún 1913 ó dá ilé-iṣẹ́ gbígbé ọkọ̀ àyọ̀kẹ́lẹ́ àkọ́kọ́ ní èkó èyí tí ó jẹ́ anfani bus service ó sì ní àwọn ọkọ̀ ńlá mẹ́ta tàkìsi mẹ́ta àti ọkọ̀ akérò mẹ́fà tí ń ṣiṣẹ́ ní ọdún 1915 obasa tún ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí olókìkí esotericist ní ọdún 1914 ó dá àjọ reformed ogboni fraternity sílẹ̀ wọ́n dá a mọ̀ gẹ́gẹ́ bí iya abiye àkọ́kọ́ tàbí ọ̀gá obìnrin ní ọdún kan náà ó kú ní ọdún 1953
|
chief temitope ajayi nigerian business consultant amina temitope ajayi aka mama diaspora jẹ́ ọmọ nàìjíríà tí ó ń gbé ní us àjùmọ̀sọ̀rọ̀ òwò tí ó ń kọ́ ìṣìrò on tàjà àwùjọ àti alákòóso aláápọn àgbègbè tèmítọ́pẹ́ àjàyí fi ìgbà kan jẹ́ ààrẹ gbogbo nigerian american congress anac akitiyan rẹ̀ àti itẹ̀síwájú àgbàwí lórí í nigerian diaspora àríyànjiyàn ti fun ní àkọ́lé ti moniker mama diaspora chief àjàyí jẹ́ mímọ̀ gidi nípa ṣíṣe ìgbéga a ìṣe-ìkúnnilágbára àwọn obìnrin àti mímú ìyà dópin ní ilè adúláwọ̀ látara agri-business látara ìdókòwò o arkansas-nigeria fórànmù àti àwọn fórànmù ìpínsíméjì ọ̀rọ̀ ajé ní us ìdúróṣinṣin àti òdodo o chief ajayi ti jẹ́ ohun-èlò ìdánilójú tí ó ń fa ọ̀pọ̀ àwọn olókòwò sínu agri-business láti us sí nigeria ó jẹ́ olùdásílẹ̀ ẹ nigerian american agricultural empowerment program naaep tí ó kọ́ni ní agricultural empowerment of farmers àwọn obìnrin àti ọ̀dọ́ ní nàìjíríà láti fi lè fi kún oúnjẹ lọ̀pọ́ àti láti ṣàkóso iṣẹ́ fún àwọn obìnrin àti àwọn ọ̀dọ́ nínu ẹ̀ka iṣẹ́ àgbẹ̀ naaep ni ìpìlẹ̀ ilé-iṣẹ́ tí ó ń kọ́ àwọn àgbẹ̀ ní 'mechanized farming system' bí ó tí ń dẹ̀rọ̀ ìṣòwò-àwìn accessibility àyẹ̀wò sí ṣíṣe iṣẹ́ àgbẹ̀ ìkórẹ̀ àti ìpolówó o ọjà wọn nílẹ̀ yí àti lókèèrè ní ọdún 2010 chief àjàyí kàn sí ìjọba àpapò orílè-èdè nàìjíríà láti dín owó èlé lórí í àwọn iṣẹ́ àgbẹ̀ kí wọ́n lè yára sí ẹ̀ka iṣẹ́ àgbẹ̀ àti láti dín ìyà kù nínú orílẹ̀-èdè yìí chief tèmítọ́pẹ́ àjàyí jẹ́ aṣojú ìjọba ti goodwill fún ìpínlẹ̀ ẹ arkansas àti maryland usa chief ms àjàyí jẹ́ àṣàyàn aṣojú fún 2014 nigeria's national conference ní bi tí ó ti jẹ́ aṣojú fún national council of women societies ncws ní nàìjíríà ó tún ṣiṣẹ́/sìn ní ìgbìmò ọ confab's agriculture nínú àdírẹ́sì i chief tèmítọ́pẹ́ àjàyí nínu ìpàdé ọdọọdún ti world bank group àti international monetary fund ó jẹ́ mímọ̀ pé “àwọn obìnrin ni ẹ̀ka agbára aláàdáni àwọn obìnrin ló ń ṣètò ìṣúná owó ní èyíkéyìí orílè-èdè nítorí pé wọ́n mọ̀ nípa è dáadáa ju àwọn ọkùnrin lọ”
|
yemisi ransome-kuti yemisi ransome-kuti ni ó jẹ́ ọmọ kan ṣoṣo ardbìmrin azariah olusegun ransome-kuti mbe tí wọ́n yàn sípò as ọ̀gá agbà onímọ̀ ìpoògùn fún orílẹ̀-èdè nàìjíríà ní ọdún 1956 tí ó sì ṣiṣẹ́ títí di ó fi fẹ̀yìn tì ní ọdún 1951 member of the most excellent order of the british empire láti ọwọ́ king george vi bákan náà ni ó tún jẹ́ ọmọ ọmọ rev canon josiah ransome-kuti ẹ̀gbọ́n rẹ̀ chief funmilayo ransome-kuti ni ó jẹ́ ajàfẹ́tó awọn obìnrin ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ni ó wà lára àwọn tí wọ́n lọ sọrọ̀ nípa ìgbòmìnira orílẹ̀-èdè nàìjíríà lọ́wọ́ àwọn briteni ransome-kuti jẹ́ ìbátan obìnrin fela kuti olikoye kuti beko ransome-kuti ati nobel prize for literature wole soyinka tí ìyá rẹ̀ náà jẹ́ ransome-kuti yemisi bí ọmọ mẹ́rin tí segun bucknor jẹ́ akọ́bí rẹ̀ láti ọdọ̀ ọkọ àkọ́kọ́ rẹ̀ captain frederick oluwole bucknor bákan náà ni ó bí mẹ́ta fún ọkọ rẹ̀ kejì dr kunle soyemi - bola soyemi seun soyemi àti eniola soyemi látàrí wípé fela kuti beko kuti ati koye kuti ti ṣaláìsí yemisi ni ó jẹ́ olórí ẹbí fún ransome-kuti ó fẹ̀yìn tì gẹ́gẹ́ bí alága fún nigerian network of non-governmental organizations nnngo ajọ tí ó dá sílẹ̀ fúnra rẹ̀ àjọ irú rẹ̀ tí ó jẹ́ akọ́kọ́ ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà tí ó ti ń ṣiṣẹ́ láti mú ìṣọ̀kan bá àwọn àjọ abẹ́lé ati ilẹ̀ òkèrè láti ọdún 1992 lásìkò ọdún 1990 ó dá àjọ girl watch kalẹ̀ àjọ tí ó ń rí sí ètò ẹ̀kọ́ àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ní ọdún 2006 wọ́n yàn án sípò olùdámọ̀ràn pàtàkì civil society lábẹ́ àjọ world bank yẹ́misí wà lára àwọn ìkan pàtàkì obìnrin tí wọ́n sapá láti mú ìdàgbà-sókè bá iṣẹ́ sdgs léte àti lé òṣì òun ìgbẹ́ sọ̀vbẹ́ láwùjọ
|
omo-oba adenrele ademola princess adenrele ademola tàbí omo-oba adenrele ademola tí a bí ní ọdún 1916 jẹ́ ọmọ-ọba kan ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà àti òṣìṣẹ́ ìlera ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè gẹ́gẹ́ bíi nọ́ọ̀sì ní ìlú london ní ọdún 1930 ó sì ń ṣiṣẹ́ rẹ̀ lọ nígbà ogun àgbáyé kejì wọ́n fi ṣe orí-ọ̀rọ̀ fún fíìmù àgbéléwò kan tí àkọ́lé rẹ̀ ń jẹ́ nurse ademola tí àwọn colonial film unit ṣe àmọ́ tí wọn ò rí mọ́ báyìí ayé rẹ̀ a bí omo-oba adenrele ademola ní ọjọ́ kejì oṣù kìíní ọdún 1916 òun ni ọmọ-ọba ladapo ademola tó jẹ́ alake ìlú abeokuta ó dé sí britain ní ọjọ́ kọkàndínlógún oṣù kẹfà ọdún 1935 ó sì kọ́kọ́ dúró sí ilé-ìgbé west african students’ union's ní camden town ní ọdún 1937 ó lọ sí àpérò ọlọ́lá kan ní britain pẹ̀lú bàbá àti ẹ̀gbọ́n rẹ̀ adetokunbo ademola ó lọ sí ilé-ìwé kan ní somerset fún ọdún méjì àwòrán ademola kan hàn nínú ìwé kan ní ọdún1942 nípa àwọn ajàfẹ́tọ̀ọ́-ọmọnìyàn lágbàáyé lórí bbc george pearson ṣe fíìmù kan nípa rẹ̀ ó pe àkọ́lé rẹ̀ ní nurse ademola àmọ́ lọ́wọ́lọ́wọ́ báyìí a ò ri mọ́
|
kemi badenoch olúkẹ́mi olúfúntọ́ badenoch /ˈbeɪdnɒk/ -nok nee adegoke born 2 january 1980 jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèlú ọmọ orílẹ̀-èdè gẹ̀ẹ́sì ó jẹ́ ọmọ ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì ní ẹkùn ìdìbò saffron walden láti ọdún 2017 títí di àkókò yìí ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú conservative party ó ti fìgbà kan jẹ́ mínísítà kéréje fún ìjọba-ìbílẹ̀ ẹ̀sìn àti àdúgbò àti mínísítà kéréje fún orí-ò-jorí bákan náà ó jẹ́ igbá-kejì sí liz truss láàárín ọdún 2021 sí 2022 àwọn òbí rẹ̀ tí wọ́n jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè nigeria bí i badenoch ní ìlú wimbledon ní london ó lo ìgbà èwe rẹ̀ ní amẹ́ríkà àti ìlú èkó lórílẹ̀ èdè nigeria ó padà sí orílẹ̀ èdè united kingdom nígbà tí ó wà lọ́mọ ọdún mẹ́rìndínlógún lẹ́yìn tí ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ìmọ̀-ẹ̀rọ kọ̀m̀pútà ní university of sussex ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí onímọ̀ ọrọ-ẹ̀rọ ní logical bákan náà ló lọ ṣiṣẹ́ ní ilé-ìfowópamọ́ royal bank ní orílẹ̀ èdè scotland gẹ́gẹ́ bí onímọ̀ ẹ̀rọ kọ̀m̀pútà kí ó tó tún ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí alájọdarí nícoutts lẹ́yìn èyí ó ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí adarí ní ilé-iṣẹ́ oníròyìn the spectator lọ́dún 2012 badenoch fìdí rẹmi nínú ìdìbò fún ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ london lẹ́yìn ọdún mẹ́ta ó gbégbá orókè nínú ìdìbò kan náà nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin london assembly badenoch jẹ́ ọ̀kan lára àwọn alágbátẹrù brexit wọ́n dìbò yàn án gẹ́gẹ́ bí aṣojú-ṣòfin ti saffron walden nínú ìdìbò 2017 lẹ́yìn tí boris johnson di ààrẹ prime minister ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì lọ́dún 2019 wọ́n yan badenoch gẹ́gẹ́ bí mínísítà fún ètò àwọn ọ̀jẹ̀ wẹ́wẹ́ lábẹ́ ìṣàkóso akọ̀wé kékeré fún ilé iṣẹ́ eleto àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ àti ètò ẹbí lẹ́yìn èyí wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bí akọ̀wé alámójútó exchequer secretary to the treasury àti parliamentary under-secretary of state for equalities lọ́dún 2020 lọ́dún 2021 wọ́n yàn án ní mínísítà kéréje fún ìjọba-ìbílẹ̀ ẹ̀sìn àti àdúgbò àti mínísítà kéréje fún orí-ò-jorí lọ́dún 2022 ó kọ̀wé fipò sílẹ̀ láti du ipò ààrẹ orílẹ̀ èdè gẹ̀ẹ́sì lábẹ́ àsíyá ẹgbẹ́-òṣèlú conservative party lẹ́yìn tí ààrẹ-àná boris johnson kọ̀wé fipò sílẹ̀
|
adenike oladosu adenike oladosu tí wọ́n bí ní 1994 jẹ́ olùgbèjà fún agbègbè àláìléwu fún àwọn ènìyàn àwùjọ ó sì tún jẹ́ olùgbèrò fún ìdaṣẹ́sílè ilé-ẹ̀kọ́ fún ojú-ọjọ́ tó tẹ́rùn ní oríléédè nàìjíríà ó tún ṣàfihàn ìṣe ojú-ọjọ́ àìléwu ní àwọn àpèjọ ilẹ̀ òkèèrè tí un climate change conference world economic forum àti elevate festival nió graz-austria ní oṣù kejìlá ọdún 2019 oladosu kópa nínú ìpàdé cop25 ní spain gẹ́gẹ́ bí i aṣojú àwọn ọ̀dọ́ nàìjíríà níbi tí sọ̀rọ̀ tó mú àwọn ènìyàn lọ́kàn nípa àyípadà ojú-ọjọ́ níilẹ̀ áfríkà àti bí ó ṣe yí àwọn ayé padà ìgbésí ayé rẹ̀ oladosu jẹ́ ọmọ ògbómọ̀ṣọ́ láti ìlú ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ nàìjíríà ó kàwé ní government secondary school gwagwalada abuja ó sì tún tẹ̀ síwájú ní ilé-ẹ̀kọ́ federal university of agriculture markurdi níbi tí ó ti gba ìpò iyì àkókọ́ nínú èkọ́ ọ̀rọ̀-ajé ajẹmọ́gbìn ní ọdún 2019 wọ́n yàn án fún ìpàdé àkọ́kọ́ ti un lórí ọ̀rọ̀ nípa ojú-ọjọ́ ní new york pẹ̀lú ìdánimọ̀ unicef gẹ́gẹ́ bíi ọ̀dọ́ tó ń mú ìyípadà dé bá ìlú ó ń darí àjọ kan tí wọ́n ń pè ní ileadclimate ní 2019 wọ́n yàn án fún ìpàdé un youth climate àkọ́kọ́ tó wáyé ní new york kò ṣàjèèjì sí ìgbìmọ̀ unicef nàìjíríà gẹ́gé bí i ọ̀dọ́ aṣèyàtọ̀ ó ń darí ìdàgbàsókè ìbílẹ̀ tí ń ṣe ileadclimate tó ń ṣègbè fún ìràpadà lake chad àti ìkópa àwọn ọ̀dọ́ nínú ìdájọ́agbègbè àláìléwu fún àwọn ènìyàn àwùjọ nípa ẹ̀kọ́
|
fila abeti aja abetí ajá túmọ̀ sí bí etí ajá ó jẹ́ orísun yorùbá ìlú ìbàdàn abetí ajá yìí ni fìlà tí a fi aṣọ òkè tàbí aṣọ àdìre rán ó jẹ́ apá kan ti aṣọ ọkọ ìyàwó máa ń wọ̀ nígbà ayẹyẹ ìgbéyàwó tàbí tí ọba ẹni ọlọ́rọ̀ àti ẹni oyè máa ń wọ̀ aṣọ òkè tí a fi ṣe fìlà abetí ajá yìí tún lè túmọ̀ sí aṣọ ipò gíga ó ní àgbékọjá méjì tó dàbí etí tó n má ń gbọ̀n bo etí ìdí èyí ni wón máa ń pè é ní abetí ajá nítorí ó dàbí etí ajá a máa ń wọ fìlà etí ajá yìí gẹ́gẹ́ bí aṣọ orí láti ṣe àfikún àwọn aṣọ abínibí bíi agbádá àṣà fìlà yorùbá yìí dàbí ìgùn onígùn mẹ́ta tí ó ní etí méjì tí ó yọ jáde bí etí ajá àṣà yìí wọ́pọ̀ láàrin ọ̀dọ àti àgbàlagbà yorùbá bákan náà àwọn onílù ìbílẹ̀ yorùbá kan fẹ́ràn láti wọ fìlà abetí ajá yìí o lè wọ irú fìlà yorùbá yìí kí o sì yí ipò àwọn ẹ̀gbẹ̀gbẹ́ padà wọ́n lè ṣe ìtọ́ka sí òkè tàbí ṣe pọ̀ díẹ̀ àṣà yìí jẹ́ ìgbà àtijọ́ àti pé ó jẹ́ olókìkí púpọ̀ pẹ̀lú aṣọ aṣọ-òkè àtijọ́
|
nigeria ministry of education ilé-iṣẹ́ àpapọ̀ ẹ̀kọ́ tí wọ́n máa ń pè ní federal ministry of education jẹ́ apá kan ti àwọn ilé-iṣẹ́ àpapọ̀ naijiria federal ministries of nigeria tí ó ń ṣe ìtọ́sọ́nà ètó-ẹ̀kọ́ ní nàìjíríà ó wà ní block 5a 8th floor federal secretariat complex shehu shagari way central area pmb 146 garki abuja ìtàn ààrẹ muhammadu buhari yan adamu adamu gbajúgbajà oníròyìn gẹ́gẹ́ bí mínísítà fún ètò ẹ̀kọ́ ní oṣù kọkànlá ọdún 2015 iṣẹ́ wa ìpinnu wa ni láti lo ètò-ẹ̀kọ́ gẹ́gẹ́ bí ohun èlò fún ìtèsíwájú ìdàgbàsókè gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà sí agbára wọn ní kíkún fún ìgbéga ti orílẹ̀-èdè tí ó lágbára tiwa-n-tiwa dọ́gbadọ́gba tí ó ní ìlọsíwájú tí a kò pin àti àìbíkítà orílẹ̀-èdè aláṣẹ lábẹ́ ọlọ́run ilé iṣẹ́ àwọn isẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú ara ilé iṣẹ́ àti àwọn ìtọ́ka sí parastatal include nbais kaduna
|
àhámọ́
|
ìmọ̀ ẹ̀dá-èdè ìmọ̀ ẹ̀dá-èdè linguistics ni ìmọ̀ nípa àbùdá èdè tí ọmọ ẹ̀dá ènìyàn n sọ tàbí sàmì sign àwọn onímọ̀ ẹ̀dá-èdè máa ń ṣe àgbéyẹ̀wò bi èdè ṣe nííṣe pẹ̀lú ìròrí àti láàkàyè àti bí àwọn eniyan ṣe ń sàmúlò èdè láàrin àwùjọ
|
shina peller shina abiola peller ojoibi 14 may 1976 je omo orile-ede naijiria otaja oloselu onise ile ise ati asòfin ni ilé ìgbìmọ̀ asòfin 9th o jẹ alaga ati oludari agba ti aquila group of companies ati club quilox shina peller ni o ni awọn akọle ijoye mejeeji ti ayedero ti ilẹ yoruba ati akinrogun ti ilẹ epe lagos nigeria ìpìlẹ̀ shina abiola peller jẹ ọmọ alhaja silifat ati ọjọgbọn moshood abiola peller o dagba ni ile musulumi iseyin ipinle oyo ni guusu-iwo-oorun naijiria ni o ti bere si o ka eko kemikali ni ladoke akintola university of technology ogbomosho nigeria nibi ti o ti gba oye akoko ni 2002 lẹhinna o gba oye oye ni iṣowo iṣowo paapaa lati ladoke akintọla university of technology ni ọdun 2013 o ṣiṣẹ ni ipinle abia ni ọdun 2003 lati mu iṣẹ iṣẹ ọdun kan ti o jẹ dandan ti national youth service corps ti o nilo fun gbogbo awọn ọmọ ile-iwe naijiria iṣẹ́ òsèlú peller je omo egbe all progressive congress o si kede erongba re lati dije labe egbe oselu all progressive congress gege bi omo ile igbimo asoju ijoba apapo to n soju agbegbe iseyin/itesiwaju/iwajowa/kajola federal constituency ni ipinle oyo ni ojo karun osu kewaa odun 2018 shina peller jawe oludije fun ile igbimo asoju-sofin lseyin/ltesiwaju/kajola/lwajowa federal constituency lori egbe all progressive congress apc fun idibo gbogboogbo odun 2019 to si jawe olubori o gba ijoko fun ile awọn aṣoju ni agbegbe rẹ ni ọjọ 23 oṣu keji ọdun 2019 lọwọlọwọ o n dije fun sẹnetọ naijiria labẹ agboorun accord party
|
hope waddell training institute colonial school in calabar cross river state nigeria hope waddell training institution howad jẹ́ ilé-ìwé ẹ̀kọ́ṣẹ́ tí ó fìkàlẹ̀ sí ìlú calabar ní ìpínlẹ̀ cross river lórílẹ̀-èdè nigeria àwọn àlùfáà ìjọ kìrìsìtẹ́nì ti united presbyterian church of scotland ni wọ́n dá a sílẹ̀ lọ́dún 1895 tí wọ́n sì só lorúkọ àlùfáà ìjọ náà nígbà náà hope masterton waddell àwọn ọ̀gá-àgbà ilé-ìwé náà láti ìbẹ̀rẹ̀ àwọn wọ̀nyí ni ọ̀gá-àgbà ilé-ìwé náà títí di ọdún 1960 síwáju
|
alakuko alakuko je agbegbe kan ni ipinle ilu ekoilu alakuko wa labe isakoso ojoroko lcdaeleyi ti arakunrin hammed tijani je olusakoso ati oludari agbegbe naa
|
muhammed ali mungeri
|
ahmad ali saharanpuri aḥmad ali saharānpuri ọdún 1810 sí ọjọ́ ẹẹ́ta-dín-lógún oṣù kẹrin ọdún 1880 jẹ́ ọ̀mọ̀wé hadith ní ilẹ̀ india tí ó kó ipa pàtàkì nínú títè jáde lítíréṣọ̀ hadīth ní india ó wà láàrin àwọn olùkọ́ àkọ́kọ́ tí mazahir uloom àti pé ìgbàgbogbo ni a kàá bí olùdásílẹ̀ fún àwọn ìlọwọ́sí rẹ̀ sí ìdàgbàsókè ilé-ẹ̀kọ́ sẹ́mínárì hadith àwọn ọmọ ilé-ìwé rẹ̀ ni muhammad qasim nanautawi àti shibli nomani ìgbésí ayé wọ́n bí aḥmad ali ní ọdún 1810 ní saharanpur ó gba al-qur’an sórí ní meerut ó sì kẹ́kọ̀ọ́ àwọn ìwé àkọ́kọ́ ní èdè lárúbáwá pẹ̀lú sa’ādat ali faqīh ní saharanpur ó lọ sí delhi níbi tí ó ti kọ́ ẹ̀kọ́ lábẹ́ àmojútó mamluk ali nanautawi ó kẹ́kọ̀ọ́ díẹ̀ nínú àwọn ẹ̀ka sahih bukhari pẹ̀lú wajīhuddīn siddīqi ó sì parí ẹ̀kọ́ nípa hadith pẹ̀lú shah muḥammad ishāq dehlawi ní ọdún 1261 hijra ní mekka gẹ́gẹ́ bí onímọ̀ ẹ̀kọ́ india syed ahmad khan ahmad ali ka gbogbo wọn ni wọ́n kẹ́kọ̀ọ́ nípa gbogbo ìwé hadith pẹ̀lú sihah sitta láti ìbẹ̀rẹ̀ sí ìparí pẹ̀lú muḥammad isḥāq abu salman shahjahanpuri síbẹ̀síbẹ̀ tọ́ka sí wípé ọ̀rọ̀ syed aḥmad khan wípé aḥmad kọ́ ẹ̀kọ́ saḥiḥ bukhāri pẹ̀lú muḥammad isḥāq kò yẹ kí wọ́n gbà syed mehboob rizwi ti gba aḥmad ali lọ́wọ́ pé ó kẹ́kọ̀ọ́ apá pàtàkì nínú saḥiḥ bukhāri pẹ̀lú wajīhuddīn siddīqi ní saharanpur ó sì tún kẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ pẹ̀lú muḥammad isḥāq ní mekka aḥmad ali padà sí india ní ọdún 1845 ó sì bẹ̀rẹ̀ aḥmadi press ní delhi láti ṣe àtẹ̀jáde àwọn ìwé hadith ó ṣe àtẹ̀jáde àwọn ẹ̀yà tí a dàkọ ti sihah sitta àti àwọn ìwé àfọwọ́kọ́ hadith tí a dàkọ ní gbogbo ìgbésí ayé rẹ̀ ó kọ́ ojú ìwé márùndínlọ́gbọ̀n ti sahiḥ bukhāri ilé-iṣẹ́ títẹ̀wẹ́ rẹ̀ jìyà pípàdánù nígbà tí ìṣọ̀tẹ̀ indian ti 1857 ó sì gbé e sí meerut ó lo ọdún mẹwàá ní kolkata tí ó ń fún àwọn ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn ní hafiz jamaluddin masjid ó padà sí saharanpur ní ọdún 1291 ah níbi tí ó ti kọ ẹ̀kọ́ ní mazahir uloom wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bí alábòójútó ilé ẹ̀kọ́ ìsìn lẹ́yìn ikú sa'ādat ali faqīh ó ṣiṣẹ́ olórí ilé-ìwé ní mazhar nanautawi ní ọdún 1294 ah nígbà gbogbo wọ́n jẹ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí olùdásílẹ̀ mazahir uloom fún ipa pàtàkì rẹ̀ nínú ìdàgbàsókè ilé-ẹ̀kọ́ ìkẹ́kọ̀ọ́ àkọ́kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ pẹ̀lú muhammad qasim nanautawi muhammad yaqub nanautawi ahmad hasan amrohi ahsan nanautawi àti shibli nomani aḥmad ali kú ní ọjọ́ kẹ́ta-dín-lógún oṣù kẹrin ọdún 1880 ní saharanpur ikú rẹ̀ jẹ́ ìtùnú nípasẹ̀ syed ahmad khan àwọn ìtọ́kasí hadhrat mawlāna aḥmad ali muhaddith sahāranpuri in deobandi nawaz in urdu sawaneh ulama-e-deoband 1 january 2000 ed deoband nawaz publications pp 243255
|
fola evans-akingbola fola evans-akingbola tí a bí ní ọjọ́ ẹ̀rìn-dín-lọ́gọ́ta ọdún 1994 jẹ́ òṣèré aláwọ̀ funfun ti british ó ṣe maddie bishop ní freeform series siren ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ ní ìlú london ni wọ́n bí evans-akingbola sí ìyá onímọ̀-ìjìnlẹ̀ ará ìlú gẹ̀ẹ́sì kan dókítà gillian evans àti bàbá rẹ̀ akọrin ilẹ̀ nàìjíríà sola akingbola ti ẹgbẹ́ jamiroquai ó dàgbà ní bermondsey pẹ̀lú ègbọ́n rẹ̀ arábìnrin rẹ̀ nígbà tí ó sì ǹ kọ́ ẹ̀kọ́ ní dulwich ó gba ẹ̀kọ́ eré ṣíṣe ní national youth theatre àti ní identity school of acting iṣẹ́ rẹ̀ ṣáájú kí ó tó bẹ̀rẹ̀ eré ṣíṣe gẹ́gẹ́ bí ọ̀jọ̀gbọ́n evans-akingbola ṣiṣẹ́ bí mọ́dẹ̀ẹ̀lì àwọn ìdánimọ̀ iṣẹ́ eré àkọ́kọ́ rẹ̀ jẹ́ fún bbc series youngers and holby city nígbà tí ó ń farahàn lórí jara kẹta ti bbc death in paradise evans-akingbola ni a sọ sínú jara olókìkí hbo game of thrones gẹ́gẹ́ bí ìyàwó kejì tí wọ́n kò sọ lórúkọ ti khal moro l'ákòókò jara kẹfà fún netflix's black mirror ìtẹ̀síwájú jara kẹrin tí ó ṣe àríyànjiyàn ní ọdún 2011 ó farahàn nínú ìṣẹ̀lẹ̀ jara 2019 kan tí a pè ní “striking vipers bí mariella arábìnrin tí ó jẹ́ ọdọ́ tó ń fẹ́ karl yahya abdul-mateen ii ẹni tí ó jẹ́ ẹgbẹ́ olú-ẹ̀dá-ìtàn ti apá eré náà láti ọdún 2018 ó ti jẹ́ ẹ̀dá-ìtàn àkọ́kọ́ lórí siren tí ń ṣeré onímọ̀-ìjìnlẹ̀ omi òkun madelyn bishop ó tún tí ṣe ìtọ́sọ́nà ṣájọpọ̀ kíkọ ìtàn ó sì ṣe àgbéjáde fíìmù kúkúrú kan tí a pè ní grandma's 80th surprise àti pé ó ṣe iṣẹ́ ohùn tí ó borí fún àwọn eré fídíò assassin's creed
|
mọfọ́lọ́jì mọfọloji jẹ ẹka ìmọ̀ ẹ̀dá-èdè linguistics ti o n ṣe agbeyẹwo ihun ọrọ ati awọn abuda rẹ mọfọlọji a maa ṣe itupalẹ ọrọ si awọn ẹyọ onitumọ to kere ju lọ ti a n pe ni mọfiimu
|
fola-evans akingbola
|
joy olasunmibo ogunmakin joy olasunmibo ogunmakin tí á bí ni 14 september 1980 tí a mọ̀ sí ayọ jẹ̀ ọ̀kọrin orílé èdè german ẹnití tí ó ma ń kọ orin silẹ àti òṣèré ó lo èdè yorùbá láti tù orúkọ rẹ̀ tí ṣe joy ni ede gẹ̀ẹ́sì sí èdè yorùbá tíì ṣe ayọ̀ èyí tí ó jẹ́ orúkọ àbísọ rẹ̀ debut album rẹ̀ tí ṣe joyful jáde ní ọdún 2006 èyí tí ó tí de music recording sales certification double-platinun status ni orílé èdè france music recording sales certification platinum ní germany àti poland bákan náà music recording sales certification gold status ní switzerland italy àti greece ilé iṣé orin interscope ní ó ṣe alágbèkalè àwo orin rẹ̀ ní orílé èdè united states ni ojó kẹẹ̀dọgún oṣù kọkànlá ọdún 2007 wọ́n bí ni frenchen èyí tí kò jìnà sí cologne ní orílé èdè germany ọ sí ní ọmọ ọkùnrin tí orúkọ kọ rẹ̀ ń jẹ́ nílé tí ó bi ní ọdún 2005 ọ sí ní ọmọ obìnrin tí í ṣe billie-eve ni oṣù keje odun ó fún olórinbkan tí orúkọ béè ni je patrick bart- williams èyí wọn tí wá ní ìpínyà ní oṣù kẹta odun 2017 ọ bí ọmọ kẹta tí orúkọ rẹ ní je jimi-julius èyí tí ó jẹ́ ọmọ kẹta kí ọdún 2002 tó parí àti òun àti àwon mọ̀lẹ́bí rẹ̀ kó lọ sí greenwich village apá kan ní manhattan ni newyork city lọ́wọ́lọ́wọ́ ó ń gbé ní brooklyn ni new york lẹyìn èyí ni ààre unicef tí orílé èdè faransé jacques hintzy ṣe ipolongo ní ọjọ́ kẹrin oṣù kejì ọdún 2009 pé òun fí okọrin náà jẹ patron unicef tí yóò má jẹ́ kí ètò fún àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ lati ní ìmọ síwájú si ní àgbáyé ilé iṣé kàn ní orílé èdè faransé marin karmitz mk2 ló ṣe àgbéjáde eré ayọ̀ joy èyí tí ó jẹ́ èdè oníṣe tí ó wà fún aádọ́rún ìṣẹ́jú tí ó lórí ìgbé ayé ọ̀kọrin ní ọdún 2009 raphael duroy ní ọ jẹ olùdarí eré náà
|
iya gbonkan margaret bandele olayinka tí a bí ní ọjọ́ ẹ̀rìn-lé-lẹ́wàá oṣù kẹsán ọdún 1958 tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí ìyá gbónkán jẹ́ òṣèré òníwòsàn ọmọ ilẹ̀ nàìjíríà tí ó jẹ́ olókìkí púpọ̀ jùlọ fún ìrísí ojú ẹ̀rù rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ ìyá gbónkán sábà máa ń ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí àjẹ́ búburú ní eré jara ti yorùbá èyí fi hàn gedegbe nípasẹ̀ ìrírí rẹ̀ ní ìbẹ̀rẹ̀ 70s ni ó jẹ́ ẹni mímọ̀ olókìkí nígbà tí ó ṣe àfihàn ní jara pa yemi elebu'bon láti ọwọ́ ifá olókùn àti ní olórí èmèrè àti ní kòtò ọ̀run tí yekinni ajileye ṣe
|
yetide badaki nigerian-born american actressyetide badaki a bi ni ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹsàn-án ọdún 1981 ó jẹ́ òṣèré ní ìlú amẹ́ríkà tó sì jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ nàìjíríà ó sì jẹ́ ẹni tí amọ̀ sí ẹni tó má ń ṣerè bilquis lóri sírìsì starz american gods ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé a bí badaki sí ìlú ìbàdàn nàìjíríà kó tó lọ sí england badaki gbé ní nàìjíríà fún ọdún mẹ́ta nígbà tó pé ọmọ ọdún mẹ́fà ó padà sí nàìjíríà ní ìparí ó bẹ̀rẹ̀ sí ní gbé amẹ́ríkà ní nǹkan bí i ọmọ ọdún méjìlá ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní mcgill university with a major in english literature theater and a minor in environmental science badaki also has a master of fine arts in theatre from illinois state university she became a united states citizen in 2014 in 2021 badaki revealed that she is bisexual career badaki received a 2006 jeff award nomination for best actress in a principal role play for i have before me a remarkable document given to me by a young lady from rwanda she has received positive reviews for her portrayal of bilquis on american gods the character of bilquis has had its role in the story expanded for the television series in 2018 badaki played the recurring character chi chi on this is us badaki has written a short film called in hollywoodland which she funded with indiegogo badaki and karen david produced and starred in the short film while jessica sherif directed it in hollywoodland is a re-imagining of alice in wonderland set in present-day los angeles in hollywoodland premiered in august 2020 at the bentonville film festival badaki will play the mother of giannis antetokounmpo in the upcoming movie rise for disney plus
|
aisha abimbola aisha abimbola tí a bí ní ọjọ́ kọkàndínlógún oṣù kejìlá ọdún 1970 tí ó sì kú ní ọjọ́ karùn-úndínlógún oṣù kàrún ọdún 2018 jẹ́ òṣèrébìnrin ti ìlẹ̀ nàìjíríà ó sì tún jẹ́ òṣèré yorùbá tó gbayì
|
école nationale de l’aviation civile école nationale de l’aviation civile je yunifasiti ni ilu toulouse ni fránsì
|
joy olasunmibo ogunmakim
|
bím̀bọ́ ọ̀ṣìn
|
bímbọ́ manuel
|
péjú ògúnmọ́lá
|
ṣadé bádérìnwá
|
kúnlé afod
|
jìmí ṣólàńkẹ́
|
dúró ládipọ̀
|
ògèdèngbé agbógungbórò
|
erik ten hag erik ten hag dutch ̍ˈeːrɪk tən ɦɑx </img> ti a bi ni ọjọ keji osu keji odun 1970 jẹ olukọni alamọdaju bọọlu ti dutch ati agbabọọlu tẹlẹ ti o tun jẹ oluṣakoso lọwọlọwọ ti ẹgbẹ agbabọọlu manchester united ni premier league gẹgẹbi ẹrọ orin kan ten hag gba bọọlu ni owo aarin-lehin ni liigi dutch fun ọdun metala ti o ṣe awọn ifarahan fun twente awọn itọka mẹta de graafschap rkc waalwijk ati utrecht o gba 199091 eerste divisie pẹlu de graafschap ati 200001 knvb cup pẹlu twente ni ọdun 2012 ten hag ni a yàn gẹgẹbi oluṣakoso go ahead eagles ni eerste divisie o tẹsiwaju lati je olukọni fun bayern munich ii lati oṣu okudu ni odun 2013 titi di ọdun 2015 lakoko rẹ bi oluṣakoso ten hag mu ẹgbẹ rẹ lọ si regionalliga bayern ten hag lẹhinna di oludari ere idaraya ati olukọni ti utrecht ni igba ooru ti ọdun 2015 ni oṣu kejila ọdun 2017 won yan gẹgẹbi olukọni agba ti ajax ati ni ọdun 2019 o dari ẹgbẹ ajax rẹ de ipele si ipari ti 2018 19 uefa champions league fun igba akọkọ lati ọdun 1997 o ṣẹgun idije iṣakoso akọkọ rẹ pẹlu ajax pẹlu 201819 knvb cup atẹle pẹlu akọle eredivisie eyiti o mu ilọpo meji fun ẹgbẹ naa ni ọdun 2021 ten hag ṣe itọsọna ajax si igbasilẹ wọn ti o gbooro si 20th knvb cup ati ni oṣu kini ọdun 2022 o di oluṣakoso to o yara julọ ni itan-akọọlẹ ajumọṣe lati de ọdo ogorun pẹlu ajax ni iyọrisi iṣe ninu ifẹsẹwọnsẹ 128 ibẹrẹ igbesi aye ten hag ni a bi ni haaksbergen overijssel iṣe bọọlu gbigba ten hag ṣere ni akọkọ bi ẹhin aarin fun twente de graafschap rkc waalwijk ati utrecht o gba l'emeta otooto pẹlu twente nibiti o ti gba knvb cup ni akoko 200001 ten hag tun gba eerste divisie pẹlu de graafschap ni akoko 199091 ọdun mẹwa ṣaaju ki o to gba ife eye pẹlu twente o fẹyìntì lati ma gba boolu ni ọdun 2002 ni eni ọjọ-ori ọdun mejilelogbon ni akoko ti o ngba fun twente lẹhin opin akoko 2001 02 eredivisie iṣẹ iṣakoso iṣẹ ibẹrẹ ni 2012 wọn yàn ten hag gẹgẹbi oluṣakoso go ahead eagles ni eerste divisie nipasẹ marc overmars ti o jẹ onipindoje ti egbẹ agbabọọlu naa lakoko akoko rẹ ni go ahead eagles o ṣe amọna ẹgbẹ agbabọọlu naa si igbega akọkọ rẹ ni ọdun metadinlogun he coached bayern munich ii lati ọjọ kefa oṣu kefa odun 2013 titi di ọdun 2015 nigbati wọn fi heiko vogel rọpo re no akoko re gẹgẹ bi olukọni ten hag dari egbẹ agbabọọlu na si regionalliga bayern lẹhinna naa ten hag di oludari ere idaraya ati olukọni ori ti utrecht ni igba ooru 2015 nibiti o ti ṣe amọna egbe agbabọọlu naa si ipo karun lakoko akọkọ rẹ ni akoko 201617 o ni ilọsiwaju pelu fc utrecht bi won se pari si ipo kẹrin ti o yẹge fun afiyẹyẹ uefa europa league ajax ni ọjọ kankanlelogun oṣu kejìlá ọdun 2017 wọn yan gẹgẹbi olukọni agba ti egbẹ agbabọọlu ajax lẹhin ti egbẹ agbabọọlu naa yọ marcel keizer kuro ni ọdun 2019 o ṣe olukọni ẹgbẹ agbabọọlu ajax rẹ si ipele ti o kangun si ipari ti 2018 19 uefa champions league fun igba akọkọ lati ọdun 1997 nipa bi o ti bori real madrid pelu 4 1 ni papa iṣere santiago bernabéu ni ti ipele 16 ati pe o tun na juventus ni 12 ninu ifẹsẹwọnsẹ naa lẹhin ti o ti ta ómí ninu ifẹsẹwọnse akọkọ 11 ni ile wọn ni ipele keji ti o kangun si ipari ni ifẹsẹwọnsẹ akọkọ ti ologbele-ipari o mu ẹgbẹ agbabọọlu rẹ mu bori 1-0 pelu egbẹ agbabọọlu tottenham hotspur ni ile re ni papa isere tottenham hotspur ti o pari laipe sibẹsibẹ ni ifẹsẹwọnsẹ keji ijanilaya idaji keji nipasẹ lucas moura fun tottenham hotspur pẹlu goolu ti o kẹhin ti o gba wọle ni iṣẹju 96th lati jẹ ki o jẹ 32 33 ni apapọ lati bori pelu goolu ita ti o si pari ireti ajax's ti odun na o ṣẹgun idije iṣakoso akọkọ rẹ pẹlu ajax ni 5 may 2019 201819 knvb cup lilu willem ii ni ipari lẹhin ọjọ mewa ti o gba ife ajax nipasẹ ten hag gba eredivisie bi daradara lẹhin ti won bori de graafschap ninu ifẹsẹwọnsẹ ti o pari 1-4 ati ki o mu wọn gba ife meji ninu egbẹ agbabọọlu naa ni ọjọ kejidinlogun oṣu kẹrin ọdun 2021 ten hag ṣe itọsọna egbe agbabọọlu ajax de 20th knvb cup won pẹlu iṣẹgun 21 lori vitesse ni ipele ipari ni ọsẹ meji lẹhinna ten hag faa adehun rẹ gun pẹlu egbe agbabọọlu ajax titi de opin akoko 202223 ni ọjọ kerindinlogun oṣu kini ọdun 2022 ten hag di oluṣakoso ti o yara julọ fi itan-akọọlẹ ajumọṣe lati ni ibori 100 pẹlu ajax ti o ṣaṣeyọri iṣẹ naa ninu ifẹsẹwọnsẹ 128 nigbati ẹgbẹ agbabọọlu rẹ lu utrecht 30 ni ọjọ ere 19 manchester united ni ọjọ kankanlelogun oṣu kẹrin ọdun 2022 wọn yan ten hag gẹgẹ bi oluṣakoso manchester united ti o bẹrẹ lati opin akoko 2021-22 titi di oṣu karun ọdun 2025 pẹlu aṣayan lati faagun fun ọdun kan siwaju won yàn mitchell van der gaag ati steve mcclaren lati darapọ mọ àwọn olukoni ti yi o ṣiṣe pelu ten hag ni ọjọ kerindinlogun oṣu karun ọdun 2022 o jẹ mimo pe ten hag ti fi ipa re ni ajax silẹ ni kiakia ati bẹrẹ igbaradi rẹ bi oluṣakoso manchester united fun akoko 2022-23
|
doyin abiola dr doyin abiola doyinsola hamidat abiola nee aboaba ti jẹ́ aṣàkóso olùdarí àti aṣàtẹ̀jáde ìwé ìròyìn national concord newspaper òun ni obìnrin nàìjíríà àkọ́kọ́ tí yóò jẹ́ olóòtú ìwé ìròyìn daily times of nigeria| nigerian daily ẹ̀kọ́ àti iṣẹ́ dr doyin abiola kẹ́kọ̀ọ́ ní yunifásitì ti ìbàdàn nàìjíríà níbi tí ó ti kẹ́kọ̀ọ́ jáde nípa èdè gẹ̀ẹ́sì àti eré-oníṣe ní 1969 lẹ́yìn tí ó kẹ́kọ̀ọ́ jáde ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ pẹ̀lú ìwé ìròyìn daily sketch ní 1969 ní àsìkò yìí ó bẹ̀rẹ̀ sí í kọ abala nínú ìwé ìròyìn náà tí wọ́n pè ní tiro tí ó ń rí sí oríṣìíríṣìí ìṣẹ̀lẹ̀ àwùjọ pẹ̀lú àwọn ọ̀rọ̀ takọtabo ní 1970 ó kúrò ní ìwé ìròyìn daily sketch ó sì rin ìrìn àjò lọ sí united states láti kẹ́kọ̀ọ́ gba master’s degree nínú journalism nígbà tí ó dé wọ́n gbà á gẹ́gẹ́ bí i akọ̀wé abala ní daily times ó sì lọ òkè láti jẹ́ ẹgbẹ́ olóòtú abala náà ó padà lọ sí new york university ó sì gba phd nínú communications and political science ní 1979 lẹ́yìn ètò phd rẹ ó padà sí daily times wọ́n sì gbé e lọ sí àjọ àwọn olóòtú níbi tí ó ti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn olóòtú tí wọ́n ti ní ìrírí bí i stanley macebuh dele giwa àti amma ogan ó jẹ́ síbẹ̀síbẹ̀ ìdúró kúkurú torí pé ìwé ìròyìn tuntun national concord newspaper tí wọ́n ṣẹ̀ dá sílẹ̀ pè é láti jẹ́ olóòtú ojoojúmọ́ rẹ àkọ́kọ́ lẹ́yìn náà ni ó dé ipò olóòtú national concord newspaper ó gba ìgbélárugẹ láti jẹ́ aṣàkóso olùdarí/olórí olóòtú ní 1986 ó di obìnrin nàìjíríà àkọ́kọ́ láti di olórí olóòtú ìwé ìròyìn ojoojúmọ́ ní nàìjíríà dr doyin abiola tún jẹ́ opó aṣàtẹ̀jáde àkọ́kọ́ àti olùdáni national concord newspaper olóyè moshood abiola tí ó fẹ́ ní 1981 iṣẹ́ doyin abiola ní national concord newspaper lọ fún ọgbọ̀n ọdún ó tún ṣiṣẹ́ ní oríṣìíríṣìí ipò ní ilé iṣẹ́ atẹ̀ròyìn ní nàìjíríà òun ni alága awards nominating panel ní nigerian media merit award àkọ́kọ́ tí wọ́n ṣe ní nàìjíríà nígbà náà ó jẹ́ ara ìgbìmọ̀ onímọ̀ràn faculty of social and management sciences ogun state university àmì-ẹ̀yẹ àti ìdánimọ̀ ó gbá àmì-ẹ̀yẹ diamond awards for media excellence dame fún ìfinjì gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀ sí ìdàgbàsókè ààlà ìmọ̀ àti ìmúlágbára ilé-iṣẹ́ ìròyìn gẹ́gẹ́ bí òpómúléró ìjọba alágbádá àwọn onídùúró dame fi ọwọ́ sí yíyàn rẹ̀ pẹ̀lú ìṣọ̀kan gẹ́gẹ́ bí i olùgbà àmì-ẹ̀yẹ lifetime achievement award níbi ayẹyẹ kẹrìnlélógún dame òun ni obìnrin kejì tí yóò gba àmì-ẹ̀yẹ dame lifetime achievement award lẹ́yìn mrsomobola onajide wọ́n fún un ní eisenhower fellowship ní 1986
|
yewande omotoso yewande omotoso tí wọ́n bí ní 1980 jẹ́ òǹkọ̀wé ìwé eré-onítàn tí ó jẹ́ olùgbé south african ayàwòrán ilé àti a-ṣe-ọ̀ṣọ́ tí wọ́n bí ní barbados tí ó sì dàgbà ní nàìjíríà ó jẹ́ ọmọbìnrin òǹkọ̀wé nàìjíríà kole omotoso àti arábìnrin aṣàgbéjáde fíìmù akin omotoso ó ń gbé ní johannesburg àwọn ìwé eré-onítàn rẹ̀ méjèèjì tí wọ́n ti tẹ̀ jáde ti fún ní ìdánimọ̀ tí ó tó àti pẹ̀lú gbígba àmì-ẹ̀yẹ south african literary award fún òǹkọ̀wé tí wọ́n tẹ iṣẹ́ rẹ̀ jáde fún ìgbà àkọ́kọ́ tí ó sì jẹ́ àṣàyàn fún south african sunday times fiction prize m-net literary awards 2012 àti 2013 etisalat prize for literature àti tí ó jẹ́ yíyàn fún 2017 bailey's women's prize for fiction ìbẹ̀rẹ̀ ayé àti ẹ̀kọ́ wọ́n bí yewande omotoso ní bridgetown barbados àti láàárín ọdún kan tí wọ́n bí i ni òun àti ìyá rẹ̀ ọmọ barbados lọ bàbá rẹ̀ ọmọ nàìjíríà àti àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin méjì sí nàìjíríà ó dàgbà ní ilé-ifẹ̀ ìpínlẹ̀ osun títí di 1992 nígbà tí ìdílé náà kó lọ sí south africa lẹ́yìn tí bàbá rẹ̀ gba iṣẹ́ akadá pẹ̀lú university of the western cape ó ti sọ láìnífiṣe iye ọdún tí mo ti gbé ní south africa mo ṣì rí ara mi bí i àbájáde ìran mẹ́ta barbados nàìjíríà àti south africa nigeria jẹ́ ará tí ó ṣe pàtàkì nínú bí mo ṣe kéèéfín ara mi ìdánimọ̀ mi àti nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò 2015 kan ó ní ìdánimọ̀ le mo fẹ́ràn jíjẹ́ ọmọ nàìjíríà mo fẹ́ràn bí mo ṣe jẹ́ ara ìdánimọ̀ náà bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé jíjẹ́ tí mo jẹ́ le torí ìdánimọ̀ púpọ̀ tí mo ní àti ìrírí ayé gbígbé kiki ó kẹ́kọ̀ọ́ architecture ní university of cape town uct àti lẹ́yìn tí ó ṣiṣẹ́ fún àwọn ọdún díẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i olùyàwòrán ilé ó lọ láti gba master's degree nínú in creative writing ní yunifásítì kan náà iṣẹ́ ìwé kíkọ rẹ̀ ìwé ìtàn àròsọ omotoso's àkọ́kọ́ bom boy ni wọ́n tẹ̀ jáde ní 2011 láti ọwọ́ modjaji books ní cape town ó gba south african literary award 2012 fún akọ̀wé ìgbà àkọ́kọ́ tí wọ́n tẹ iṣẹ́ rẹ̀ jáde wọ́n yàn án fún sunday times fiction prize ti south africa àti fún m-net literary awards 2012 bom boy tún gbé ipò kejì fún 2013 etisalat prize for literature lẹ́yìn tí omotoso bẹ̀rẹ̀ etisalat fellowship 2014 ní university of east anglia tí ẹni tí ó gba ẹ̀bùn 2013 noviolet bulawayo fi sílẹ̀ fún un omotoso jẹ́ 2013 norman mailer fellow ó sì gbá miles morland scholarship ní 2014 gẹ́gẹ́ bí i bom boy ìwé ìtàn àròsọ rẹ̀ kejì the woman next door chatto and windus 2016 gba àyẹ̀wò tí ó dára pẹ̀lú publishers weekly tí wọ́n pè é ní this charming touching occasionally radiant tale of two prickly octogenarians two women one black and one white neighbours who discover after 20 years of exchanging digs and insults that they might help each other omotoso captures the changing racial relations since the 1950s as well as the immigrant experience through personal detail and small psychological insights into mixed emotions the artist’s eye and the widow’s remorse hers is a fresh voice as adept at evoking the peace of walking up a kopje as the cruelty of south africa’s past irish independent ṣe àpèjúwethe woman next door gẹ́gẹ́ bí i a finely observed account of female prejudice redemption and that often elusive commodity - friendship wọ́n yàn án fún bailey's women's prize for fiction ní 2017 àti wọ́n yàn án fún international dublin literary award ti 2018 omotoso ti ṣe àfikún àwọn ìtàn àti ewì sí àtẹ̀jáde oríṣìíríṣìí lára wọn konch noir nation speaking for the generation contemporary stories from africa contemporary african women’s poetry kalahari review the moth literary journal one world two the 2012 caine prize anthology and new daughters of africa 2019 tí margaret busby ṣe àtúntò rẹ̀ ó jẹ́ olùkópa láti ìgbà dé ìgbà àwọn ọdún iṣẹ́ ọnà lára wọn ni aké arts and book festival edinburgh international book festival àti pen american world voices festival wọ́n ti mọ omotoso ní àwọn àwùjọ kan fún ìlò àtinúdá rẹ̀ fún àwọn àwòrán afìmọ̀sílára hàn bí ìbòjú juju tí wọ́n sọ lórúkọ ní déédéé
|
mahmud hasan deobandi mahmud hasan deobandi tí a tún mọ̀ sí shaykh al-hind 18511920 jẹ́ onímọ̀ mùsùlùmí india àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ìrìn òmìnira india tí ó pẹ̀lú dá yunifásítì jamia millia islamia sílẹ̀ àti dá silk letter movement fún òmìnira india ó jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ àkọ́kọ́ láti kẹ́kọ̀ọ́ ní ilé ẹ̀kọ́ ẹ̀sìn darul uloom deoband àwọn olùkọ́ rẹ̀ jẹ́ muhammad qasim nanautawi àti mahmud deobandi ó sì ní àṣẹ nínú sufism nípa imdadullah muhajir makki àti rashid ahmad gangohi hasan ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí i olùkọ́ àgbà darul uloom deoband ó sì ṣẹ̀dàá àwọn ẹgbẹ́ bí i jamiatul ansar àti nizaratul maarif ó kọ ìtumọ̀ kùránì ní urdu ó sì kọ àwọn ìwé ìwé bí i adilla-e-kāmilah īzah al-adillah ahsan al-qirā àti al-jahd al-muqill ó kọ́ hadith ní darul uloom deoband àti ṣe àtúnṣe ẹ̀dà sunan abu dawud lára àwọn akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ gbòógì ni ashraf ali thanwi anwar shah kashmiri hussain ahmad madani kifayatullah dehlawi sanaullah amritsari àti ubaidullah sindhi hasan jẹ́ olódì british raj paraku ó bẹ̀rẹ̀ àwọn ìrìn láti borí agbára wọn ní india ṣùgbọ́n wọ́n mú u ní 1916 wọ́n sì tì í mọ́lé ní malta wọ́n tú u sílẹ̀ ní 1920 wọ́n sì fi oyè shaykh al-hind fún un the leader of india láti ọwọ́ khilafat committee ó kọ àwọn edicts ẹ̀sìn ní àtìlẹ́yìn non-cooperation movement ó sì rin ìrìn àjò lọ sí oríṣìíríṣìí apá ilẹ̀ india láti gba àwọn mùsùlùmí sí inú ìrìn òmìnira ó jẹ́ aṣáájú lórí ìpàdé gbogboogbò kejì ti jamiat ulema-e-hind ní oṣù kọkànlá 1920 wọ́n sì yàn án ní ààrẹ wọ́n sọ orúkọ shaikh-ul-hind maulana mahmood hasan medical college ní ìrántí r rẹ̀ ní 2013 ìjọba india fi commemorative postal stamp lórí lẹ́tà ìrìn sílíìkìì rẹ̀ léde ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé wọ́n bí mahmud hasan ní 1851 ní ìlú bareilly ní uttar pradesh òde-òní india sínú ìdílé usmani deoband bàbá rẹ̀ zulfiqar ali deobandi tí wọ́n jọ dá darul uloom deoband jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n ní bareilly college ó sì ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí i igbákejì aṣàyẹ̀wò madrasas hasan kẹ́kọ̀ọ́ kùránì pẹ̀lú miyanji manglori àti persian pẹ̀lú abdul lateef láàárín 1857 rebellion wọ́n gbé bàbá rẹ̀ lọ sí meerut wọ́n sì ṣí hasan lọ deoband níbi tí ó ti kẹ́kọ̀ọ́ lítíréṣọ̀ persian àti arabic láti kọ́ọ̀sì dars-e-nizami pẹ̀lú ọ́ńkù rẹ̀ mehtab ali ó di akẹ́kọ̀ọ́ àkọ́kọ́ ní darul uloom deoband ó sì kẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú mahmud deobandi ó káàdì ẹ̀kọ́ àìgbẹ̀fẹ̀ rẹ̀ ní 1869 ó sì lọ sí meerut láti kẹ́kọ̀ọ́ sihah sittah pẹ̀lú muhammad qasim nanautawi ó lọ àwọn àpérò hadith nanautawi fún ọdún méjì ó sì kẹ́kọ̀ọ́ lítíréṣọ̀ arabic pẹ̀lú bàbá rẹ̀ ní àwọn àkókò ìsinmi ó kẹ́kọ̀ọ́jáde ní 1872 ó sì gba ìwérí iyì ní 1873 ní ayẹyẹ ìkẹ́kọ̀ọ́jáde àkọ́kọ́ darul uloom deoband ó jẹ́ ọmọlẹ́yìn imdadullah muhajir makki àti rashid ahmad gangohi nínú sufism iṣẹ́ darul uloom deoband wọ́n yan hasan gẹ́gẹ́ bí i olùkọ́ ní darul uloom deoband ní 1873 ọdún kan náà tí ó parí ẹ̀kọ́ rẹ̀ ó di ọ̀gá olùkọ́ ní 1890 kò ro ilé-ẹ̀kọ́ ẹ̀sìn deoband gẹ́gẹ́ bí ibi ìkẹ́kọ̀ọ́ nìkan ṣùgbọ́n ibi tí wọ́n dásílẹ̀ fún dídí ìpàdánù 1857 rebellion hasan dá thamratut-tarbiyat the fruit of the upbringing sílẹ̀ ní 1878 wọ́n dá a sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i ibi ọpọlọ láti kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti àwọn akẹ́kọ̀ọ́jáde darul uloom deoband ó wá gba ìrísí jamiatul ansar àwùjọ àwọn olùrànlọ́wọ́ tí ó bẹ̀rẹ̀ ní 1909 pẹ̀lú ìpàdé rẹ̀ àkọ́kọ́ tí ó wáyé ní moradabad tí ahmad hasan amrohi sì darí lẹ́gbẹ̀ẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ ubaidullah sindhi hasan bẹ̀rẹ̀ nizaratul ma'arif al-qur'ānia ilé-ẹ̀kọ́ fún ìkẹ́kọ̀ọ́ kùránì ní oṣù kọkànlá 1913 ó gbìyànjú láti ṣe àfikún agbára àwọn onímọ̀ mùsùlùmí lórí àti láti ṣe ìsọfúnni àti kọ àwọn mùsùlùmí tí wọ́n kẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú èdè gẹ̀ẹ́sì nípa ìsìláàmù hussain ahmad madani gbèrò pé ìdí tí ó wà lẹ́yìn ìdásílẹ̀ nizaratul maarif ni láti jẹ́ kí àwọn ọ̀dọ́ mùsùlùmí di onígbàgbọ́ tí ó rinlẹ̀ àti láti kìlọ̀ àti láti tọ́ wọn sọ́nà pàápàá àwọn mùsùlùmí tí ó kàwé nílànà àwọn òyìnbó ní àwọn ẹ̀kọ́ inú kùránì ní ọ̀nà tó mọ́pọlọ dání tí yóò yọ ipa májèlé tí àwọn ìsọkiri tí ó lòdì sí ti ìsìláàmù àti àwọn iyèméjì tí wọ́n rí ní ọ̀nà àìtọ́ nípa ìṣe ìgbàgbọ́ àti ọ̀nà ìsìláàmù ní ayé òde-òní ìrìn lẹ́tà sílíìkì hasan fẹ́ gba agbára lọ́wọ́ british raj ní india láti ṣe èyí ó tẹjúmọ́ agbègbè ilẹ̀ méjì àkọ́kọ́ ni agbègbè àwọn ẹ̀yà tí ó dá dúró tí wọ́n ń gbé láàárín afghanistan àti india asir adrawi sọ èyí ni ìbáyému onítàn pé àwọn ènìyàn tí wọ́n rọ́ wá india gba ọ̀nà náà àti yíyàn tí hasan yan agbègbè yìí fún ìrìn rẹ̀ jẹ́ dájúdájú ẹ̀rí tí ó ga jù nípa ìwọ̀túnwòsí rẹ̀ àti àfojúsùn agbègbè kejì wà láàárín india ó fẹ́ nípá lórí àwọn adarí olóòótọ́ tí wọ́n bìkítà fún àwùjọ láti ṣe àtìlẹ́yìn fún èròǹgbà rẹ̀ àti nínú èyí ó ṣe àṣeyọrí díẹ̀ lára àwọn onímọ̀ tí wọ́n ṣiṣẹ́ ní ipele àkọ́kọ́ ni àwọn akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ àti àwọn ẹnìkejì bí i abdul ghaffar khan abdur-raheem sindhi muhammad mian mansoor ansari ubaidullah sindhi àti uzair gul peshawari wọ́n ṣe ìgbédìde ètò hasan sínú àwọn agbègbè iwájú àti àwọn tí wọ́n jẹ́ ẹ̀yà tí ó dá dúró àwọn onímọ̀ tí wọ́n ṣiṣẹ́ lórí ipele kejì jẹ́ mukhtar ahmad ansari abdur-raheem raipuri àti ahmadullah panipati muhammad miyan deobandi sọ shaikhul hind máa ń rọra wo àwọn ìwà àti agbára àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ àti àwọn ènìyàn tí wọ́n wá bá a ó yan àwọn ènìyàn kan láàárín wọn ó sì pàṣẹ fún wọn láti dé yaghistan àti mú àwọn ẹ̀yà tí ó dá dúró náà kógun ja india ètò tí wọ́n ṣe láti gbaradì fún àwọn ara inú india fún ìlòdìsí tí àwọn ìjọba afghani àti turkish bá pèsè ohun ogun fún àwọn ológun àti àwọn ènìyàn láàárín india dìde fún ìlòdìsí nígbà ìkọlù àwọn ológun yìí yaghistan jẹ́ àárín ìrìn mahmud hasan akẹ́kọ̀ọ́ hasan ubaidullah sindhi àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ ni wọ́n ṣe ètò provisional government of india wọ́n sì yan mahendra pratap gẹ́gẹ́ bí ààrẹ hasan fúnra rẹ̀ rin ìrìn-àjò lọ sí hejaz láti gba àtìlẹ́yìn àwọn german àti turkish ní 1915 ó kúrò ní bombay ní ọjọ́ 18 oṣù kẹsàn-án 1915 àwọn tí wọ́n sì sìn ín ni àwọn onímọ̀ bí i muhammad mian mansoor ansari murtaza hasan chandpuri muhammad sahool bhagalpuri àti uzair gul peshawari ní ọjọ́ 18 oṣù kẹwàá 1915 ó lọ sí mecca níbi tí ó ti ní àwọn ìpàdé pẹ̀lú ghalib pasha gómìnà turkish àti anwar pasha tí ó jẹ́ mínísítà ààbò turkey ghalib pasha fun ní ìdánilójú lórí ìrànlọ́wọ́ ó sì fún un ní lẹ́tà mẹ́ta ọ̀kan tí wọ́n kọ sí àwọn mùsùlùmí india èkejì sí gómìnà busra pasha àti ìkẹta sí anwar pasha hasan tún ní ìpàdé pẹ̀lú djemal pasha gómìnà syria tí ó gbà pẹ̀lú ohun tí ghalib pasha ti sọ hasan bẹ̀rù pé tí òun bá padà lọ india àwọn òyìnbó lè ti òun mọ́lé ó sì bèrè kí wọ́n jẹ́ kí òun dé ibodè afghanistan níbi tí òun ti lè dé yaghistan djemal wá nnkan sọ ó sì sọ fún un pé tí ó bá ń bẹ̀rù àtìmọ́lé ó lè dúró ní hejaz àbí agbègbèkágbègbè turkey mìíràn ní ṣísẹ̀ntẹ̀lé wọ́n lu awo ètò tí wọ́n pè ní ìrìn lẹ́tà sílíìkì wọ́n sì ti àwọn ọmọ ẹgbẹ́ náà mọ́lé wọ́n mú hasan ní oṣù kejìlá 1916 pẹ̀lú àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ àti àwọn akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ hussain ahmad madani àti uzair gul peshawari láti ọwọ́ sharif hussain the sharif of mecca tí wọ́n ṣe lòdì sí àwọn turks tí wọ́n sì sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn òyìnbó sharif náà wá fi wọ́n lé àwọn òyìnbó lọ́wọ́ wọ́n sì tì wọ́n mọ́lé ní fort verdala ní malta ìrìn khilafat wọ́n tú hasan sílẹ̀ ní oṣù karùn-ún 1920 nígbà tí ó máa di ọjọ́ 8 oṣù kẹfà 1920 ó ti dé bombay lára àwọn onímọ̀ ńlá àti olóṣèlú tí wọ́n kí i káàbọ̀ ni abdul bari firangi mahali hafiz muhammad ahmad kifayatullah dehlawi shaukat ali àti mahatma gandhi wọ́n rí ìtúsílẹ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbéga ńlá sí ìrìn khilafat wọ́n sì fi oyè shaykh al-hind gbé iyì fún un olórí india láti ọwọ́ àjọ khilafat hasan jẹ́ ìwúrí fún àwọn onímọ̀ ilé-ẹ̀kọ́ ẹ̀sìn deoband láti dara pọ̀ mọ́ ìrìn khilafat náà ó ṣe òfin ẹ̀sìn láti yẹra fún àwọn ọjà òyìnbó tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ muhammadan anglo-oriental college máa ń ṣètò nínú òfin rẹ̀ ó gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́ níyànjú láti yẹra fún ṣíṣe àtìlẹ́yìn fún ìjọba lọ́nàkọnà kí wọ́n yẹra fún àwọn ilé-ìwé àti ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí ìjọba ń kówó lé kí wọ́n sì yẹra fún àwọn iṣẹ́ ìjọba lẹ́yìn òfin rẹ̀ yìí ọ̀pọ̀ akẹ́kọ̀ọ́ ni wọ́n kúrò ní ilé-ẹ̀kọ́ náà òfin yìí ṣe àtìlẹ́yìn non-cooperation movement hasan wá rin ìrìn-àjò lọ sí allahabad fatehpur ghazipur faizabad lucknow àti moradabad ó sì tọ́ àwọn mùsùlùmí sọ́nà ní àtìlẹ́yìn àwọn ìrìn náà jamia millia islamia wọ́n ní kí hasan darí ayẹyẹ ìpìlẹ̀ jamia millia islamia tí wọ́n mọ̀ sí national muslim university ní àkókò náà olùdásílẹ̀ yunifásítì yìí ni hasan pẹ̀lú muhammad ali jauhar àti hakim ajmal khan tí ìwúrí wọn jẹ́ àwọn ìbéèrè àwọn akẹ́kọ̀ọ́ aligarh muslim university amu tí wọ́n ní ìjákulẹ̀ pẹ̀lú àwọn ìyàtọ̀ iṣẹ́ àwọn òyìnbó amu tí wọ́n sì fẹ́ yunifásítì tuntun àwọn ìránṣẹ́ hasan síbẹ̀síbẹ̀ gbà á níyànjú láti má gba ohun tí wọ́n fi lọ̀ ọ́ yìí nítorí ó ti ń ní àìlera ó sì ti ń rẹ̀ ẹ́ látàrí àsìkò rẹ̀ ní àtìmọ́lé ní malta hasan sọ ní ìdáhùn sí àwọn ẹ̀rù wọn tí jíjẹ ààrẹ mi bá dùn àwọn òyìnbó nígbà náà ni màá kópa nínú ayẹyẹ yìí dájúdájú wọ́n gbé e wá sí ibùdókọ̀ ọkọ ojú-irin ní deoband nínú palanquin láti ibi tí ó ti rin ìrìn-àjò lọ sí aligarh hasan ò rí ohunkóhun kọ ó sì rán akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ shabbir ahmad usmani láti ṣètò ọ̀rọ̀ ààrẹ rẹ̀ lẹ́yìn náà ni ó ṣe àwọn àtúnṣe àti àtúntò sí ọ̀rọ̀ tí wọ́n pèsè sílẹ̀ ó sì tẹ̀ ẹ́ jáde ní ọjọ́ 29 oṣù kẹwàá 1920 usmani sì ka ọ̀rọ̀ yìí síta ní ayẹyẹ ìfilélẹ̀ yunifásítì náà lẹ́yìn tí hasan fi òkuta ìpìlẹ̀ jamia millia islamia lélẹ̀ hasan sọ nínú ọ̀rọ̀ náà pé àwọn ènìyàn tí wọ́n ní ìmọ̀ láàárín yín mọ̀ dájú pé àwọn olórí àti aṣáájú mi ò pa àṣẹ àìgbàgbọ́ lórí kíkọ́ èdè àjèjì àbí níní ẹ̀kọ́ sáyẹ́ǹsì àwọn ìran mìíràn bẹ́ẹ̀ni wọ́n sọ ọ́ pé ipa ìkẹyìn ẹ̀kọ́ èdè gẹ̀ẹ́sì ni pé àwọn tí wọ́n ń wá a yálà máa ń kun ara wọn nínú ti kìrìtẹ̀ẹ́nì àbí kí wọ́n yọ ẹ̀sìn wọn tàbí àwọn ìdàkejì ẹ̀sìn jálẹ̀ àfojúdi àìgbàgbọ́ wọn àbí kí wọ́n sin ìjọba wọn lọ́wọ́lọ́wọ́ nígbà náà ó dára láti wà nípò àìmọ̀ kàkà kí ènìyàn lọ fún irú ẹ̀kọ́ bẹ́ẹ̀ ó gbà pẹ̀lú mahatma gandhi tí ó sọ pé ẹ̀kọ́ gíga àwọn ilé-ẹ̀kọ́ yìí mọ́ bí i wàrà ṣùgbọ́n tí wọ́n pò pọ̀ pẹ̀lú ìwọ̀nba májèlé díẹ̀ tí wọ́n sì kà sí muslim national university gẹ́gẹ́ bí i asẹ́ tí yóò ya májèlé yìí kúrò nínú ẹ̀kọ́ jamiat ulema-e-hind hasan jẹ́ adarí lórí ìpàdé gbogboogbò kejì àwọn jamiat ulema-e-hind tí ó wáyé ní oṣù kọkànlá 1920 ní delhi wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bí ààrẹ àwọn jamiat ipò tí kò ti lè ṣiṣẹ́ nítorí ikú rẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀ ní ọjọ́ 30 oṣù kọkànlá wọ́n ṣe ìpàdé gbogboogbò yìí fún ọjọ́ mẹ́ta bẹ̀rẹ̀ láti ọjọ́ 19 oṣù kọkànlá àti akẹ́kọ̀ọ́ hasan shabbir ahmad usmani sì ka ọ̀rọ̀ ààrẹ rẹ̀ síta hasan jà fún ìrẹ́pọ̀ hindu-muslim-sikh ó sì sọ pé tí àwọn ẹlẹ́ṣin hindu àti àwọn mùsùlùmí bá sowọ́pọ̀ gbígba òmìnira ò lè le àpérò ìkẹyìn tí hasan lọ nìyìí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ hasan jẹ́ òǹkà ní ìlọ́po ẹgbẹ̀rún lára àwọn akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ gbòógì ni anwar shah kashmiri asghar hussain deobandi ashraf ali thanwi husain ahmad madani izaz ali amrohi kifayatullah dihlawi manazir ahsan gilani muhammad mian mansoor ansari muhammad shafi deobandi sanaullah amritsari shabbir ahmad usmani syed fakhruddin ahmad ubaidullah sindhi àti uzair gul peshawari ebrahim moosa sọ pé àwọn ọ̀wọ́ akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ tí ó dára padà di mímọ̀ nínú ẹ̀ka madrasa wọ́n sì ṣe àfikún sí ìgbé ayé àwùjọ ní apá gúúsù asia ní àwọn pápá tí ó fẹjú bí i ẹ̀kọ́ ẹ̀sìn ìṣèlú àti kíkọ́ ilé-ẹ̀kọ́ àwọn iṣẹ́ rẹ̀ tí ó wà ní àkọsílẹ̀ ṣíṣe ìtumọ̀ kùránì hasan kọ ìtumọ̀ kùránì ní urdu ní ìfẹ̀gbẹ́kẹ̀gbẹ́ pẹ̀lú ti ìpìlẹ̀ lẹ́yìn náà ni ó bẹ̀rẹ̀ sí ṣe àlàyé ìtumọ̀ yìí pẹ̀lú àwọn àkọsílẹ̀ àlàyé bí ó ṣe jẹ́ ó ṣẹ̀ parí orí kẹrin an-nisa nígbà tí ó kú ní 1920 akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ shabbir ahmad usmani ni ó parí iṣẹ́ ìtúpalẹ̀ kíkún yìí wọ́n sì tẹ̀ ẹ́ jáde gẹ́gẹ́ bí i tafsir-e-usmāni lẹ́yìn èyí ní àwọn ọ̀wọ́ onímọ̀ kan tú u sí èdè persia mohammed zahir shah ni ó gbé iṣẹ́ fún wọn ọba tí ó jẹ kẹ́yìn ní afghanistan al-abwāb wa al-tarājim li al-bukhāri hasan jẹ́ olùkọ́ sahih bukhari ní darul uloom deoband fún ìgbà pípẹ́ àti pé nígbà tí ó wà ní ẹ̀wọ̀n ní malta ó bẹ̀rẹ̀ sí kọ iṣẹ́ tí ń ṣàlàyé àwọn àkọ́lé orí rẹ̀ nínú ẹ̀kọ́ hàdíítì pípín àkọ́lé orí nínú àṣàyàn iṣẹ́ jẹ́ ohun tí wọ́n rí bí i sáyẹ́ǹsì tí ó yàtọ̀ hasan bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú òfin aléélẹ̀ márùndínlógún lórí orí ọ̀rọ̀ náà lẹ́yìn náà ni ó sọ̀rọ̀ lórí àwọn ìṣe láti inú orí náà lórí ìfihàn àti ṣiṣẹ́ lórí orí tí ó wà fún ìmọ̀ lábọ̀ wọ́n sọ iṣẹ́ náà ní al-abwāb wa al-tarājim li al-bukhāri ó sì jẹ́ ojú ewé 52 adilla-e-kāmilah bí ìrìn ahl-i hadith ṣe ń gbòòrò sí i ni india ni wọ́n ṣe bẹ̀rẹ̀ sí béèrè àṣẹ hanafi school of thought onímọ̀ ahl-i hadith muhammad hussain batalvi ṣe àkójọpọ̀ ìbéèrè mẹ́wàá ó sì ṣe ìkéde ìpè ìjà pẹ̀lú ẹ̀bùn fún àwọn tó bá ní ìdáhùn pẹ̀lú rupees mẹ́wàá lórí ìbéèrè kọ̀ọ̀kan wọ́n tẹ èyí jáde láti amritsar wọ́n sì fi ránṣẹ́ lọ sí darul uloom deoband ìṣe deoband ni láti yẹra fún àwọn ọ̀rọ̀ náà tí ó ń pín àwùjọ mùsùlùmí ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn ahl-i hadith fi ipá mú ọ̀rọ̀ náà bákan náà hasan ní ìbéèrè olùkọ́ rẹ̀ nanautawi ní ìdáhùn béèrè àwọn ìbéèrè kan ní ọ̀nà ìwé adilla-e-kāmilah ní ìlérí pé tí ẹ bá dáhùn àwọn ìbéèrè wọ̀nyìí a máa fún un yín ní ogún rupees lórí ìbéèrè kọ̀ọ̀kan īzah al-adillah lẹ́yìn adilla-e-kāmilah mahmud hasan onímọ̀ ahl-i hadith kan ahmad hasan amrohwi kọ misbāh al-adillah ní ìdáhùn sí adilla-e-kāmilah onímọ̀ deobandi yìí dúró fún àkókò díẹ̀ fún ìdáhùn kankan láti ọ̀dọ̀ oníbèérè àkọ́kọ́ muhammad hussain batalwi tí ó kéde lẹ́yìn náà pé iṣẹ́ amrohwi kún ojú òṣùwọ̀n àti pé òun ní ti òun ti ko gbogbo èrò láti kọ àwọn ìbéèrè náà kúrò ní ọkàn mahmud hasan ní ìdáhùn kọ izāh al-adillah àsọyé lórí iṣẹ́ rẹ̀ ìṣáájú adilla-e-kāmilah ahsan al-qirā hasan ti sọ̀rọ̀ lóri níní ìrun àdúrà ọjọ́-ẹtì ní àwọn abúlé àti ìletò nínú ìwé yìí syed nazeer husain tí gbé ọ̀rọ̀ yìí dìde ó sì ti ṣe àtẹ̀jáde àkọsílẹ̀ ẹ̀sìn tí ó sọ pé kò sí ìsọnípàtó ibikíbi fún àwọn àdúrà ọjọ́ etì ó sọ pé níbikíbi tí ó kéré jù ènìyàn méjì bá ti péjọ àwọn àdúrà ọjọ́ etì ti ṣe pàtàkì amòfin àti onímọ̀ hanafi rashid ahmad gangohi kọ fatwa ó lé ní ojú ewé mẹ́rìnlá ní ìdáhùn tí ó pè ní awthaq al-'urā láti ojú ìwòye hanafi school of thought iṣẹ́ gangohi gba àtúpalẹ̀ lámèyítọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn onímọ̀ ahl-i hadith púpọ̀ èyí tí àbájáde wọ́n jẹ́ àwọn àríyànjiyàn kan náà akẹ́kọ̀ọ́ gangohi mahmud hasan rò ó pé èdè inú àwọn iṣẹ́ wọ̀nyìí jẹ́ ti àfojúdi ó sì kọ ìwé tí ó gùn tí wọ́n pè ní ahsan al-qirā fī tawzīḥ awthaq al-'urā ní ìdáhùn al-jahd al-muqill shah ismail dehlvi àti àwọn ẹmẹ̀wà rẹ tí wọ́n ṣiṣẹ́ lórí àtúntò àwọn mùsùlùmí láti bidʻah àwọn àrà ẹ̀sìn tuntun gba ìbẹnu-àtẹ́-lù ńlá láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn tí wọ́n ní àjọṣepọ̀ pẹ̀lú àwọn àrà tuntun wọ̀nyìí wọ́n fi ẹ̀sùn ìsọ̀rọ̀ òdì sí ẹ̀sìn dehlvi wọ́n sì yọ ọ́ kúrò nínú ìsìláàmù bákan náà onímọ̀ ìsìláàmù ahmad hasan kanpuri kọ tanzih al-raḥmān inú èyí tí ó ti dárúkọ dehlvi láti jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ọmọ ẹgbẹ́ agbẹ́sìnlérí muʿtazila mahmud hasan ní ìdáhùn kọ al-jahd al-muqill fī tanzīhi al-mu'izzi wa al-muzill ní ìpele méjì ìwé náà sọ̀rọ̀ lórí àwọn àwọn ìṣesí àti àbùdá allah pẹ̀lú àwọn kókó ọ̀rọ̀ ilm al-kalam ní títẹ̀lé ìsọ̀rọ̀sí àsọyé al-taftazani sharah aqā'id-e-nasafi lórí ìgbàgbọ́ al-nasafi hasan ti dáhùn sí àwọn ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan shah ismail dehlvi àti àwọn onímọ̀ mìíràn bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú lílo ilm al-kalam tas'hīh abu dawūd wọ́n ṣe ìpamọ́ àwọn ìwé àfọwọ́kọ tó wà ní àkọsílẹ̀ ní yàrá ìkàwé ìran ìsìláàmù pẹ̀lú ọ̀pọ̀ rẹ̀ tí wọ́n dìmú ní mecca àti medina onímọ̀ india ahmad ali saharanpuri ṣe ẹ̀dà àwọn ìwé àfọwọ́kọ náà tí ó wà ní mecca ó sì kà wọ́n lẹ́yìn náà pẹ̀lú shah muhammad ishaq nígbà tí ó padà sí india ó bẹ̀rẹ̀ sí í ṣe àtẹ̀jáde àwọn ẹ̀dá àtúnṣe àtẹ̀jáde àfọwọ́kọ àwọn hadith wọ̀nyìí láti ilé iṣẹ́ atẹ̀wé rẹ̀ akẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ muhammad qasim nanautawi tẹ̀síwájú lórí ìṣe ṣíṣe ẹ̀dá àwọn ìwé àfọwọ́kọ hàdíítì títí tí gbogbo ìwé náà fi di títẹ̀jáde ní india lẹ́yìn náà ìdí wà láti ṣe àtúnṣe ẹ̀dà sunan abu dawud ọ̀kan lára àwọn ìwé mẹ́fà pàtàkì jùlọ hadith àmọ́ ṣá àwọn àtúnṣe tí wọ́n tẹ̀ jáde àti àkọsílẹ̀ ìwé àfọwọ́kọ tó ṣáájú yàtọ̀ gedegbe sí ara wọn hasan fún ìdí yìí gba gbogbo ìwé àfọwọ́kọ tí ó wà nílẹ̀ ó ṣe àtúnṣe àwọn ọ̀rọ̀ náà ó sì ṣe àtẹ̀jáde àtúnṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ ní ọ̀nà ìwé àwọn wọ̀nyìí ni wọ́n tẹ̀ jáde ní 1900 láti ilé-iṣẹ́ atẹ̀wé mujtabai ní delhi ikú àti ẹ̀yin rẹ̀ ní ọjọ́ 30 oṣù kẹwàá 1920 ọjọ́ kan lẹ́yìn ìpìlẹ̀ jamia millia islamia ní aligarh hasan rin ìrìn àjò lọ sí delhi ní ìbéèrè mukhtar ahmad ansari ọjọ́ púpọ̀ lẹ́yìn náà ìlera rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ sí í dínkù ó sì gba ìtọ́jú láti ọwọ́ ansari ní ilé rẹ̀ ní daryaganj ó kú ní ọjọ́ 30 oṣù kọkànlá 1920 ní delhi bí wọ́n ṣe kéde ìròyìn ikú rẹ̀ àwọn hindu àti àwọn mùsùlùmí ti àwọn ilé ìtajà wọn wọ́n sì péjọ síta ilé ansari láti ṣe ìjúbà sí hasan ansari wá béèrè lọ́wọ́ arákùnrin hasan hakeem muhammad hasan tí ó bá fẹ́ kí wọ́n sin mahmud hasan sí delhi pẹ̀lú ìpèsè ètò sí ilẹ̀ ìsìnkú mehdiyan tàbí tí ó bá fẹ́ láti sin ín sí deoband pẹ̀lú ìpèsè ètò fún gbígbé òkú náà lọ wọ́n pinnu láti sin ín sí deoband nítorí ìfẹ́ rẹ̀ pé kí wọ́n sin ín sí ìtòsí sàárè olùkọ́ rẹ̀ muhammad qasim nanautawi wọ́n gba àwọn àdúrà ìsìnkú rẹ̀ ní ọ̀pọ̀ ìgbà àwọn ará delhi ṣe àwọn àdúrà náà ní ìta ilé ansari àti lẹ́yìn náà wọ́n gbé òkú náà lọ sí deoband bí wọ́n ṣe dé ibùdókọ̀ ọkọ̀ ojú-irin delhi ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn péjọ wọ́n sì ṣe àdúrà ìsìnkú bákan náà wọ́n ṣe àdúrà ní ibùdókọ̀ ọkọ ojú-irin meerut àti ibùdókọ̀ ọkọ̀ ojú-irin meerut cantt àdúrà ìsìnkú rẹ̀ karùn-ún àti ìkẹyìn ni àbúrò rẹ̀ hakeem muhammad hasan darí wọ́n sì sin ín sí ilẹ̀ ìsìnkú qasmi mahmud hasan ti ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀yẹ ashraf ali thanwi pè é ní shaykh al'-'ālam olórí ayé thanwi sọ pé ní òye tiwa òun ni olórí india sindh àwọn arab àti àwọn ajam wọ́n sọ ilé-ẹ̀kọ́ ìwòsàn ní saharanpur ní shaikh-ul-hind maulana mahmood hasan medical college lẹ́yìn rẹ̀ ní oṣù kìíní 2013 ààrẹ india pranab mukherjee ṣe àgbéjáde ontẹ̀ ìfìwéránṣẹ́ lórí silk letter movement hassan ní ìrántí àwọn ìtọ́kasí àwọn ìwé ìtọ́kasí <templatestyles src=refbegin/stylescss /> al-qasim academy jamia abu hurairah 9 https//edinburghuniversitypresscom/book-what-is-a-madrasahtml oclc https//archiveorg/details/tazkiramashaikhdeobandbymuftiazizurrehman https//ussagepubcom/en-us/nam/madrasas-in-the-age-of-islamophobia/book272358 https//booksgooglecom/booksid=uxfuaaaamaaj https//wwwjstororg/stable/44141303 retrieved 30 july 2021 42 5 709722 doi jstor https//wwwjstororg/stable/4284490 retrieved 27 july 2021 tí a bá fẹ́ kà sí i oclc
|
muhammad adil khan muḥammad adil khan tàbí adil khān 1957 10 october 2020 jẹ́ onímọ̀ mùsùlùmí ti orílẹ̀-èdè pakistan òun sì ni ọ̀gá ilé-ìwé jamia farooqia wọ́n mọ̀ ọ́n gẹ́gẹ́ bíi gbajúgbajà onímọ̀ mùsùlùmí ní pakistan khan jẹ́ akẹ́kọ̀ọ́ gboyè ti ilé-ìwé jamia farooqia àti university of karachi ó sì kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní international islamic university malaysia fún ọdún mẹ́jọ láti ọdún 2010 wọ ọdún 2018 àwọn agbanipa kan ni wọ́n pa á ní ìtòsí ilé-ìtajà kan ní shah faisal colony karachi ní ọjọ́ kẹwàá oṣù kẹwàá ọdún 2020 ìtàn ìgbésíayé rẹ̀ wọ́n bí muhammad adil khan ní ọdún 1957 òun ni ọmọkùnrin tí saleemullah khan bí ó kẹ́kọ̀ọ́ gboyè ní ilé-ìwé dars-e-nizami láti ọwọ́ jamia farooqia ní ọdún 1973 ó gba ba nínú ẹ̀kọ́ human science ní ọdún 1976 àti ma nínú ẹ̀kọ́ arabic ní ọdún 1978 àti òye phd nínú ẹ̀kọ́ islamic culture ní ọdún 1992 láti university of karachi khan ṣe ìdásílẹ̀ ilé-ìwé islam ní lodi california fún àwọn ọ̀jẹ̀ wẹ́wẹ́ àwọn ọlọ́pàá ti ìlú us gbé òun àti ọmọ rẹ̀ ọkùnrin wọ́n sì ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò fún wọn kí wọ́n tó dá wọn padà sí ìlú wọn ní ọdún 2005 khan ni akọ̀wé fún ilé-ìwé jamia farooqia seminary ní ìlú karachi láti ọdún 1986 wọ 2010 òun ni ọ̀jọ̀gbọ́n international islamic university malaysia from 2010 to 2018 ó padà lọ sí ìlú pakistan lẹ́yìn ikú bàbá rẹ̀ saleemullah khan ní ọjọ́ karùn-úndínlógún oṣù kìíní ọdún 2017 ó sì di ọ̀gá ilé-ìwé àti ọ̀jọ̀gbọ́n hadīth ní jamia farooqia lẹ́yìn náà ó fi àbúrò rẹ̀ ubaidullāh khālid sípò olùdarí ẹ̀ka shah faisal colony ti farooqia seminary àwọn àmì-̀ẹ̀yẹ khan gba àmi ẹyẹ ti irawọ mààrun lati ọdọ ilè iwe giga ti malaysia ni ọdun 2018 àwọn ìwé lítíreṣọ̀ rẹ̀ ìwé mẹ́tẹ̀ẹ̀ta tí khan kọ lórí ìmọ̀ àti ọ̀làjú islam ofin ati fiqh fun gbógbó èniyan àti ìwó àgbàyè islam wà lára àwọn ìwé tí ó kọ tí ó wà nínú kòríkúlọ́ọ̀mù ilè iwè giga ti islam malaysia àwọn ìwé rẹ̀ mìíràn ni
|
ebrahim desai south african muslim scholar and jurist 19632021 ebrahim desai ọjọ́ ẹ̀rìn-dín-lógún oṣù kìíní ọdún 1963 sí ọjọ́ márùn-ún dín lógún oṣù kéje ọdún 2021 jẹ́ onímọ̀ ìjìnlẹ̀ ẹ̀sìn mùsùlùmí orílẹ̀-èdè south africa àti olófin tí ó ṣe ìdásílẹ̀ darul iftaa mahmudiyyah ojú askimam fatawa àti pé ó jẹ́ olùkọ́ àgbà ti hadith ní madrasah in'aamiyyah ó jẹ́ ọmọ ilé-ìwé ti jamiah islamiah talimuddin dabhel àti pé ó wà láàrin ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta àwọn mùsùlùmí tí ó ní ipa jùlọ ó kọ́ àwọn ìwé pẹ̀lú òrọ̀ àsọyè lórí qaseedah burdah ọ̀rọ̀ ìsáájú sí hadīth àti ọ̀rọ̀ ìsáájú sí ìṣòwò ìsìlámù ìgbésí ayé rẹ̀ wọ́n bí ebrahim desai ní ọjọ́ ẹ̀rìn-dín-lógún-lógún oṣù kìíní ọdún 1963 ní richmond natal ó kọ́ quran sórí ní waterval islamic institute àti pé ó kẹ́kọ̀ọ́ ìbílẹ̀ dars-i nizami ní jamia islamia talimuddin ní gujarat orílẹ̀-èdè india ó dá lórí islamic jurisprudence lábẹ́ ahmad khanpuri ó tún tẹ̀síwájú pẹ̀lú grand mufti ti darul uloom deoband ti tẹ́lẹ̀ mahmood hasan gangohi òǹkọ̀wẹ́ ti multi-volume fatawa mahmudiyyah ó sì dí ọmọ-ẹ̀hìn rẹ̀ tí a fún ní àṣẹ ní sufism desai jẹ́ olùkọ́ ní madrasah ta῾līmuddīn ní òkun isipingo fún ọdún mẹ́wàá àti pé ó jẹ́ olórí ẹ̀ka fatwa ti jamiatul ulama kwazulu natal ó sìn gẹ́gẹ́ bí ọ̀jọ̀gbọ́n àgbà ti hadith ní madrasah in’aamiyyah fún ọdún mẹ́wàá mìíràn ó sì ṣe olórí darul ifta rẹ̀ ní oṣù kẹta ọdún 2008 ó rin ìrìn-àjò lọ sí hong kong láti kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ní islamic kasim tuet memorial college ní ọdún 2011 ó yípadà sí durban ó sì ṣètò darul iftaa mahmudiyyah ní sherwood ó kọ́ sahih bukhari ní darul uloom nu'maniyyah ó sì darí darul iftaa mahmudiyyah tí ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ ní sherwood ní ọdún 2000 ó bẹ̀rẹ̀ ìbéèrè imam fatawa portal ìbéèrè ìsìlámù lórí ẹ̀rọ ayélujára àti ibi ìpamọ́ ìdáhùn èyí tí a rò pé ó ti fún un l'ókìkí ní àgbáyé gẹ́gẹ́ bí v šisler ebrahim desai ṣe àpẹẹrẹ ọ̀mọ̀wé kan tí ó bíótilẹ̀jẹ́pẹ́ ó ti kọ́ ẹ̀kó ní ilé-ẹ̀kọ́ tí kìí ṣe azhari ní ìta àgbáyé arab gba ìdánimọ̀ àgbáyé nípasẹ̀ àtìlẹ́yìn púpọ̀ tí a kójọpọ̀ nípasẹ̀ àlàyé àti ìmọ̀-ẹ̀rọ ìbánisọ̀rọ̀ desai ṣiṣẹ́ bí alága fnb islamic finance's shari'ah board ó bẹ̀rẹ̀ sharī῾ah complaint business campaign ní ọdún 2002 “àpéjọ kan láti kọjú àwọn ọ̀ràn ìṣòwò òde òní ní ìṣòwò islam àti ọ̀rọ̀ owó” ní ìbámu sí ojú òpó wẹ́ẹ̀bù darul iftaa mahmudiyyah ó wà lára àwọn ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ènìyàn tí wọ́n ṣe àfihàn gẹ́gẹ́ bí mùsùlùmí tí ó ní ipa jùlọ nípasẹ̀ àkójọpọ̀ ti royal islamic strategic studies centre namira nahouza tọ́ka sí i gẹ́gẹ́ bí “south african grand mufti ti ọmọ orílẹ̀-èdè india” àwọn ọmọ ilé-ìwé rẹ̀ ni abrar mirza faisal al-mahmudi àti husain kadodia farhana nínú ìwádìí rẹ̀ tọ́ka sí pé desai fúnra rẹ̀ jẹ́ olùkọ́ ńlá sí àwọn ọmọ ilé-ìwé ti darul ifta mahmudiyyah ilé-ẹ̀kọ́ ibi tí ó ti kẹ́kọ̀ọ́ àti láti ibi tí gbogbo àwọn fatwa ti gbà jáde ìwádìí ti ìṣètò ti fatwa lórí askimamorg ní 2011 fi hàn pé nígbà tí àwọn ọmọ ilé-ìwé desai gbilẹ̀ láti agbègbè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ wọ́n ṣe àgbéjáde fatwa púpọ̀ àti bí olùkọ́ olùwà ó jẹ́ aláṣẹ tó gbẹ́hìn gẹ́gẹ́ bí a ti fihàn nípasẹ̀ ìlà ìparí ní ìparí fatwa kọ̀ọ̀kan 'ṣàyẹ̀wò àti fọwọ́sí nípasẹ̀ mufti ebrahim desai desai kú ní ọjọ́ àrùn-dín-lógún oṣù kéje ọdún 2021 ní durban abdur rahman ibn yusuf mangera muhammad ibn adam al-kawthari omar suleiman àti yasir nadeem al wajidi fi ìbànújẹ́ hàn lórí ikú rẹ̀ àwọn iṣẹ́ lítíréṣọ̀ rẹ̀ àwọn ìlànà ẹ̀sìn desai ti jẹ́ àtẹ̀jáde gẹ́gẹ́ bí contemporary fatawa ní apá mẹ́rin àwọn iṣẹ́ rẹ̀ mìíràn ni
|
suzanne iroche suzanne olufunke iroche tàbí suzanne olufunke soboyejo-iroche jẹ́ òṣìṣẹ́ báǹkí ní orílé èdè nàìjíríà èyí tí ó ń darí finbank tí orílé èdè nàìjíríà ìgbé ayé iroche lọ sí ilé ìwé gírámà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ queen's college èyí tí ó wà ní ìpínlè èkó àti fásitì tí amọ̀ sí unilag lẹyìn èyí ní ọ lọ sí kellogg school of managemet ni illionois bákan náà ó jẹ́ adarí àgbà fún ilé ifowopamọsi tí amò sí globa banki directorate ọ sí wá lára àwọn elétò fún pension managemet reform fún ilé ìfowópamọ́ united bani god africa uba ó di mímọ kàà nígbà tí rògbòdìyàn bá àwọn ilé ìfọwópamọ́si ní orílé èdè nàìjíríà ìgbà yẹn ní wọ́n gba ṣé lé àwọn àgbà adarí bánkì marun-un ni oṣù kẹjọ ọdún 2009 tí wọn sì fí àwọn márùn míràn èpò wọ èyí tí òǹtẹ̀ sí wà láti ilé ìfọwópamọ́si gbogboògbò tí ó ń jẹ́ cbn igbákejì gómìnà sarah alade ní ọ fí iroche jẹ́ adarí bánkì finland ní nàìjíríà èyí tí bí rọ́pò okey nwosu lára àwọn tí wọn jẹ adarí bánkì mìíràn tí wọn rí lóyè náà ní ceo tí union bánkì dr batu ebong tí olufunke iyabo osibodu rọ́pò rẹ àti cecilia ìbẹrù tí john aboh tí oceanic bank rọ́pò rẹ̀ ní ọdún 2019 ní wọ́n fí jẹ adarí àgbà ti amọ̀ sí executive director fún ilé iṣé kàn tí ó ń jẹ́ united africa company of nigeria uac tí ó èpò ẹni awuneba ajumogobia tí ó daṣẹ sílẹ̀ ni ipari oṣù keje
|
amy jadesimi nigerian businesswoman amy jadesimi ibí 1976 jẹ́ oníṣòwò orílé èdè nàìjíríà àti adarí àgbà fún ilé iṣé deep offshore logistics base tí ó wà ní ìpínlè èkó ladol èyí tí bí jẹ́ ilé iṣé aládání tí ó ń ṣe iṣé logistics àti engineering ní ogbà tí wón mọ̀ sí port of lagos
|
tosin oshinowo tosin oshinowo jẹ́ oníṣòwò òṣèré ayàwòrán-ilé orílẹ̀-èdè nàìjíríà àwòrán ilé-ìtajà ńlá ti maryland to yà ni ó sọ ọ́ di ìlúmọ̀ọ́ká akẹ́kọ̀ọ́ gboyè ilé-ìwé kingston college ìlú london ni tosin ó sì tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀ ni bartlett school of architecture ọ̀pọ̀ iṣẹ́ ni tosin ti ṣe ni ilẹ̀ yìí àti ní òkè-òkun ni ọdún 2012 ní ọdún 2012 tosin dá ilé-isẹ́ rẹ̀ cmdesign atelier sílẹ̀ bẹ́è náà ni tosin oshinowo jẹ aláṣẹ àti olùdásílẹ̀ ilé-iṣẹ́ ile ila house of lines ní ọdún 2019 oshinowo jẹyọ nínú ìwé orúkọ polaris visual collaborative ṣe ìfẹ́ tosin sí ìyàwònrán-ilé kíkọ́ jẹyọ láti ara ohun ti o fẹran láti ìgbà èwe rẹ nínú ìfọ̀rọ̀-wáni-lẹ́nuwò pèlú omenkaonlinecom tosin ni àṣeyọrí òun nínú iṣẹ́ yíya àwòrán àti ìmọ̀ nípa yíya àwònrá ni ọmọ ọdún méjìlá pẹ̀lú ìmọ̀ nípa ilé kíkọ́ ló mú òun yan iṣẹ́ ti òun n ṣe láàyò iṣẹ́ tó yàn láàyò yíyàn tí tosin yan iṣẹ́ àwòrán yíyà tí wà nínú rè láti ìgbà èwe rẹ̀ nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan tí ó ṣe pẹ̀lú omenkaonlinecom ó sọ ọ́ di mímọ̀ pé iṣẹ́ tí òun yàn láàyò wáyé nípa ṣíṣe àwárí ohun àtinúdá ara rẹ̀ àṣeyọrí rẹ̀ nínú isẹ́ technical drawing tí wọ́n ṣe ní ilé-ìwé girama àti òye láti mọ̀ nípa yíya àwòrán nígbà tí ó sì kéré ó tún ní àǹfààní láti rí àwọn iṣẹ́ lọ́lọ́kan-ò-jọ̀kan bíi ilé bàbá rẹ̀ tí wọ́n ń kọ́ nígbà kan ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ìgbáradì rẹ̀ london sí rotterdam 20072009 ní kété tí ó parí ilé-ìwé girama kí ó tó kúrò ní ìlú london tosin ṣiṣẹ́ pẹ̀lú skidmore owning àti merril's llp ní london láàárín oṣù kẹfà sí oṣụ̀ kẹwàá ọdún 2007 lẹ́yìn náà ó lọ sí metropolitan architecture ní rotterdam láti oṣù kìíní ọdún 2008 sí oṣụ́ kìíní ọdún 2009 níbẹ̀ ni ó ti wà lára ọ̀wọ́-ẹléni-mẹ́fà tó ń ṣe dìsáìnì afárá kẹrin ti mainland tí ó yẹ kí ó ṣe ìsopọ̀ ajah àti ikorodu ní ìpínlẹ̀ èkó james cubitt architects ní ìlú nàìjíríà ní oṣù kìíní ọdún 2009 lẹ́yìn ìdánilẹ́kọ̀ọ́ tí ó gbà ní ìlú europe àti ìgbáradì ọdún díẹ̀ tosin padà sí ìlú nàìjíríà ó sì dara pọ̀ mọ́ james cubitt architects níbi tí ó ti ṣiṣẹ́ lórí iṣẹ́ nigerian liquefied natural gas nlng gẹ́gẹ́ bíi adarí ayàwòrán nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò tí ó ṣe pẹ̀lú future lagos' ayo denton ó sọ ọ́ di mímọ̀ pé iṣẹ́ náà kọ́ òun ó sì la ojú òun sí ìlọ́wọ́sí àwọn stakeholders nínú iṣẹ́ náà tosin ṣiṣẹ́ pẹ̀lú james cubitt fún ọdún mẹ́rin ní kété tí ó kúrò ní james cubitt architects tosin bẹ̀rẹ̀ ilé-iṣẹ́ tirẹ̀ cmdesign atelier cmd+a ní ọdún 2012 ìṣẹ̀dálè yìí ló mú àbáwáyé dìsáìnì tí wọ́n ṣe fún maryland mall ní ìpínlẹ̀ èkó pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ mìírán ti ilé-iṣẹ́ náà ti ṣiṣé lórí sho-n-tell tosin oshinowo ni olùdarí ètò sho-n-tell èyí tó jẹ́ ètò alákànṣe ọlọ́dọọdún tó máa ń fàyè sílè fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ university of lagos yàlá èyí tó ṣì ń kàwé lọ́wọ́ àti èyí tó ti kàwé tán láti pín yàrá-ìyàwòrán pẹ̀lú àwọn ayàwòrán tó gbòógì èyí wà láti mú ìmọ̀ wọn gbòòrò si nípa ìṣínilójú sí iṣẹ́ àwọn àmọ̀dájú àárín wọn ètò náà wáyé láti ọdún 2009 títí wọ 2014 ile ila tosin oshinowo ṣe ìdásílẹ̀ ilé ìlà house of lines ní ọdún 2017 èyí tó jẹ́ ilé-iṣẹ́ tó ń rí sí ṣíṣẹ àwọn ẹ̀ṣọ́-ilé lóríṣiríṣi
|
olawunmi banjo olawunmi banjo tí a bí ní ọjọ́ kọkànlélógbọ̀n oṣù keje ọdun 1985 jẹ́ olùyàwòrán ọmọ orílè-èdè nàìjíríà ìpínlè èkó ni ó ń gbé tí ó sì ti ń ya àwórán ayé rè a bí banjo sí ìpínlè ogun nàìjirià o ka ìwé ní yunifásitì ti pan africa àwọn nǹkan tí ó fi ń yàwòrán ni èèdú àti akiriliki lórí kanfasi ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwòrán rẹ̀ jẹ́ àwòrán alálàyé àti àpèjuwe àwon ènìyàn sì lè mọ nǹkan tí àwòrán náà túmò sí tàbí tí ó ń gbìyànjú láti sọ láìṣe pé ẹlọ̀mìíràn ṣàlàyé fún won ọlawunmi sọ pé àwon nǹkan tó jẹ́ ìwúrí fún òun láti máa yàwòrán ni awọn ohun ìṣẹ́dá lóríṣiriṣi awon ènìyàn tí o yiká àti sísé akiyesi sí àwon nkan tí ó wà layika rè olawunmi jé okan lara omo egbe african artists foundation
|
muhammed ali mungeri
|
faizul waheed faizul waheed tí wọ́n tún mọ̀ sí faizul waheed qāsmī wọ́n bí ní ọdún 1964 tí ó sì fi ayé lẹ̀ ní ọjọ́ kìíní oṣù kẹfà ọdún 2021 jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n ẹ̀sìn ìsìláàmù onímọ̀ òfin ẹ̀sìn ìsìláàmù àti onímọ̀ ìtumọ̀ kòrání jammu àti kashmir tí ó jẹ́ olórí àwọn múfútí fún markaz-ul-ma'arif ẹgbẹ́ àwọn olùkọ́ fún ẹ̀sìn ìsìláàmù ní bathindi jammu ó kọ haiz al-mannān kòránì àkọ́kọ́ tó tú sí àti ní àlàyé ní èdè gojri àwọn ìwé rẹ̀ faizul waheed kọ faiz al-mannān ìtumọ̀ al-qur’an àkọ́kọ́ láíláí ní èdè gojri àwọn iṣẹ́ rẹ̀ mìíràn pẹ̀lú
|
tobi amusan olúwatóbilọ́ba ayọ̀midé tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí tóbi amúsàn tí wọ́n bí lọ́jọ́ kẹtàlélógún oṣù kẹrin ọdún 1997 jẹ́ ẹlẹ́sẹ̀ ehoro asáré-díje pàápàá jù lọ eré orí pápá oníwọ̀n ọlọ́gọ́rùn mítà ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjíríà òun ni ó borí nínú ìdíje 2022 world athletics championships nínú eré-ìjẹ oníwọ̀n ọlọ́gọ́rùnún mítà pẹ̀lú àṣeyọrí ìṣẹ́jú àáyá tó kéré jù lọ lágbàáyé ní ìṣẹ́jú 1206 ṣáájú àṣekágbá ère-ìjẹ náà ní abala tó ṣáájú àṣekágbá ó ti kọ́kọ́ ṣàṣeyọrí èyí láàárín ìṣẹ́jú-àáyá 1212 péré èyí tí ẹnikẹ́ni kò ṣe rí ní gbogbo àgbáyé tóbi kópa nínú eré-ìjẹ ti commonwealth lọ́dún 2018 bẹ́ẹ̀ náà ló kópa nínú ti ilẹ̀ adúláwò áfíríkà ti ọdún 2018 bákan náà bẹ́ẹ̀ náà ló kópa ní african games ní ẹ̀mejì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ tí ó sìn borí ó gbé ipò kìíní nínú ìdíje diamond league trophy lọ́dún 2021 nínú eré-ìjẹ oníwọ̀n mítà ọgọ́rùn-ún ní ìlú zurich
|
sonya clark sonya clark tí a bí ní washington dc ni odun 1967 jé oluya/oluse aworan ní orílè-èdè amerika orisirisi nkan ni sonya n fi se àwòrán àwon nkan bi òwú aso irun ènìyàn àti béèbéè lo baba clark jé dokita tí óun toju wèrè ní trinidad ìyá clark sì jé noosi láti jamaica àwon ènìyàn nínú idile clark ni o jé orisun iwuri fun láti di oluyaworan
|
nkechi blessing sunday nigerian actress nkechi blessing sunday a bíi ni ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kejì ọdún 1989 jẹ́ olùgbé ilẹ̀ amẹ́ríkà òṣèré orílẹ̀-èdè nàìjíríà olóòtú fíìmù adarí fíìmù àti screenwriter wọ́n tọ dàgbà ní surulere ní ìpínlẹ̀ èkó ó ṣàgbéjáde fíìmù àkọ́kọ́ rẹ̀ omoege lekki ní ọdún 2015 tí òun tìkalára rẹ̀ jẹ́ akópa pẹ̀lú yinka quadri ní ọdùn 2016 omoege lekki gba àwọ́ọ̀dù maya wọ́n sì yan-an fun revelation of the year nínú best of nollywood awards ó tún ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí adarí àti alákoso àgbà ní ilé tí ń ṣe àwọn fíìmù ti nkechi àti nbs foundation ìgbé-ayé ní ìbẹ̀rẹ̀-pẹ̀pẹ̀ nkechi blessing sunday jẹ́ ọmọ bíbí ìlú abia ìpínlẹ̀ kan ní apa ibìkan ní gúsù-àríwá ti orílẹ̀-èdè naijiria ó ka ẹ̀kọ́ àkọ́ bẹ̀rẹ̀ rẹ ní ilé-ẹ̀kọ́ ní olu abiodun ní ìpínlẹ̀ èkó àti ẹ̀kọ́ gíga ní barachel model college ní ìpínlẹ̀ èkó ó kọ́ ẹ̀kọ́ olóṣù mẹ́fà ti diploma lórí ìmọ̀ theatre arts ní fásitì ti ìpínlẹ̀ èkó ó sì kọ́ ẹ̀kọ́ ìmọ̀ international relations ní fásitì houdegbe north american career ní ọdún 2008 lẹ́yìn tí ó ti kẹ́kọ̀ọ́ jáde láti fásitì ti ìpínlẹ̀ èkó ọ̀rẹ́ rẹ̀ kemi korede ṣàwárí ìfẹ́ nkechi sí eré ṣíṣe ó sì lò ó gẹ́gẹ́ bí akópa nínú eré-àgbéléwò rẹ̀ omo bewaji omo bewaji jẹ́ àlùyọ ráḿpẹ́ fún-un nínú iṣẹ́-àyànṣe rẹ̀ tí ó sì mu mọ emeka duru tí ó rànlọ́wọ́ láti kópa nínú emem isong movie la iná àti òṣùṣù ọdún 2009 ó di ìlú mọ̀ọ̀ká ní ọdún 2012 pẹ̀lú ipò olú-ẹ̀dá-ìtàn nínú kafila omo ibadan lẹ́yìn ìpàdé rẹ̀ pẹ̀lú olóótú náà temitope bali ní ìlú south africa tí ó fún-un ní ipò olú-ẹ̀dá ìtàn nínú kafila omo ibadan ní ọjọ́ kínní oṣù kejì ọdún 2017 the nigeria carnival usa ṣàfihàn rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan lára àwọn aṣojú wọn nínú abala kejì ti ayẹyẹ ọlọ́dọọdún orin àṣà àti ẹ̀fẹ̀ nàìjíríà ní orílẹ̀-èdèamerika ní ọdún 2018 ó kó ipa ẹ̀dá ìtàn tí wọ́n pè ní dora nínú fíìmù the ghost and the tout ní́èyí tí ó bí àwọ́ọ̀dù fún ní ọdún 2018 city people movie award fún àwọn òṣèré'bìnrin tó kátò jùlọ lọ́dún ní ọdún 2020 nkechi blessing darí ètò african entertainment awards usa ti ọdún 2018 papọ̀ pẹ̀lú seun sean jimoh ní ọdún yẹn náà ó wà lára àwọn òṣèré inú fate of alakada gẹ́gẹ́ bí ẹ̀dá ìtàn tí ń ṣe bisi ó jẹ́ olú-ẹ̀dá ìtàn nínú tanwa savage the cleanser omo emi àti ise ori àti ipò amúgbálẹ̀gbẹ́ olú-ẹ̀dá ìtàn nínú breaded life àti olori amolegbe personal life divorce rate is so high because people are ready for weddings not marriage… ya all waiting for me to post my wedding pictures before you believe i am married…lmao i nbs wants marriage and not a wedding ain’t ready to make my relationship your entertainment ” -nkechi blessing ní̀ ọjọ́ kẹwàá oṣù kẹfà ọdún 2021 nkechi blessing sojú abeńkòó nípa ìgbéyàwó òun àti òṣèlú ìpínlẹ̀ ekiti náà falegan opeyemi david lẹ́yìn tí ó fọ́n àwọn àwòrán ìgbéyàwó wọn sórí ìkànni instagram ní ọjọ́-ìbí ẹ̀ ní ọjọ́ ketàlélógún oṣù kẹsàn-án ọdún 2021 ó pàdánù ìyá rẹ gloria obasi sunday nígbà tí ó ń gbaradì fún ìfilọ́lè àwọn eré-àgbéléwò rẹ̀ tí ó ṣeyebíye ní theatre èkó tí ó tóbi jùlọ ní ọjọ́ kefà oṣù kérin ọdún 2022 nkechi blessing fi léde lórí ìkànnì instagram rẹ̀ pé òun ti fòpin sí ìgbéyàwó òun tí ó pé oṣù mẹ́wàá pẹ̀lú falegan opeyemi david filmography àwọn fíìmù látọwọ́ nkechi blessing sunday
|
amu jadesinmi
|
dj cuppy florence ifeoluwa otedola á bí ní ójó kókànlá osù kòkànlá ódún 1992 tí á mọ̀ ní ọ̀jọ̀gbọ̀n sí dj cuppy tàbì cuppy nìkán ó jẹ́ disc jockey nàíjíríà àtí ólùpílẹ́ṣẹ́ ó jé ómọ́bínrín ónísòwò nàíjíríà femi otedola ó dágbà ní ìlù èkò ó sí lọ́ sí ìlù lọndọn ní ọ́mọ́ ọ́dún kétàlà ígbésí áyé ìbẹ̀rẹ̀ àtì ẹ̀kọ̀ cuppy gbé ní ilupeju fún ọ́dún mẹ́fà kí ó tó lọ́ sí ikeja níbítí ó tí lọ́ sí grange school ikeja lẹ́hìnnà ó tún pádà sí ìlù lọndọn fún àwọ́n gcse rẹ̀ àtí àwọ́n ìpélé a ó párí ílé-ìwè gígà ní king's college london ní óṣù kéjé ọ́dún 2014 pẹ̀lú óyè nínù íṣòwò àtí ètò-ọ́rọ̀ ájé ó tún gbá ìwè èrí gígá sí ní ìṣòwò órín látí yúnífásítì new york ní ọ́dún 2015 cuppy kọ́ ẹ̀kọ́ fún ìwè èrì gígà sí ní àwọ́n ẹ̀kọ́ áfíríká ní yúnífásítì tí oxford ó wólé ní 2021 ó sì párì nì 2022 ìṣẹ́-ṣíṣé ní 2014 cuppy nì dj ólùgbè ní mtv africa music awards ní durban lẹ́hìnnà ó ṣéré ní tatler àtí christie's art ball ní ìlù lọndọn àtì ní ìpàdè ìgbàdùn financial times business ni ílù mexico ní óṣù kéjé ọ́dún 2014 ó sé àgbékálè house of cuppy sílẹ̀ gẹ́gẹ́bì ákójọ̀pọ̀ àkòpò àkọ̀kọ̀ rẹ̀ ní ìlù lọndọn àtí èkò ṣáájú ṣíṣé ìfìlọ́lẹ̀ rè ní ìlù new york ní ọjọ́ kéjì óṣù kẹ́san ọ́dún 2014 pèlú house of cuppy ó ṣé àgbéjádè àwọ́n àtúnṣè edm-esque ti àwọ́n orín nípásẹ̀ àwọ́n òṣèrè afropop tí wón táyo ní ọ́dún kánnà cuppy tún ṣe ifílọ́lẹ̀ ìṣákósó órín tí ó wá ní ìlù lọndọn àtí ìṣòwò íṣélọ́pọ̀ akóònù red velvet music group ní óṣù kíní ọ́dún 2015 cuppy jé ìfìhàn lórí òjú tí ìwè ìròhìn life guardian ójú ìwè náà jé áyẹ́yẹ́ ìrán túntún tí àwọ́n óbìnrìn áfíríká ní óṣù kẹ̀tá odún 2015 cuppy ni òsìsè dj fún 2015 oil barons charity ni dubai ó sí jé òlórín áfríkà akọkọ lati kórín ní íbí áyéyé náà o jẹ́ àfíhán ní 2015 ósù kẹ́rìn / ósù kárúùn atejade ti forbes woman africa ni oṣu kárúùn ọ́dún 2015 cuppy gbé house cuppy ii kálè ní òṣù kẹ́jọ̀ ọ́dún 2015 cuppy ṣétò sí ìr̀in-àjò dj ákọ́kọ́ rẹ́ sí àwọ́n órílé-édè méjò ni afirika tí àkólé rè jé “cuppy takes africa” ó ṣàbẹ̀wò sí náìjíríà senegal ghana kenya tanzania rwanda uganda ati south africa irin-ajo cuppy takes africa pẹ̀lú àwọ́n ìṣẹ́ ṣíṣé àwọ́n ìfówósòwòpó ólórín pàtàkì àtí àwọ́n ìṣẹ́-ọ̀fẹ́ tí ó nì àtìlẹ́yín gtb bank ati dangote foundation léyín ígbá díè ní ódún kánnà ó dáwón láràyà ni jay-z 's roc nation ní óṣù kẹ́wà ọ́dún 2016 ìrìn-àjò “cuppy takes africa” sé àfíhàn lòrí fox life africa gẹgẹbi jara iwe-ipinlẹ ní ódún 2016 cuppy jẹ́ òlúgbé dj fun uncommon sense mtv2 pèlú charlamagne tha god ó ṣé áwọ́n órín méjì vibe ati the way i am èyítí ó jé àfíhàn lori afrobeats ep nípàsẹ̀ young paris èyìtì ó gbé jádè ni òjó kérìn-lé-lógún ósù kétá ódún 2017 ní ọ́jọ́ kétàláà óṣù kẹ́wà ọ́dún 2017 ó sé ágbékálè green light” ísé órín éléyókán àkókó rẹ̀ órín náà sé áfíhán óhùn nlá ólórín àtí ólùpịlèsè tekno látì náijíríà ní ọ̀jọ́ ógbòn óṣù kẹ́tá ọ́dún 2018 ó gbe\ “vybe” silẹ ìsé órín éléyókaln ékéjì rẹ órín náà sé áfíhàn óhuln nlá látì ghana sarkodie ní òjó kérìn-lé-lógún óṣù kẹ̀jọ̀ ọ̀dún 2018 ó gbé currency sítá ìsé órín éléyókaln kẹ́tá rẹ̀ tí ó sé àfíhàn lax
|
temie giwa-tunbosun temie giwa-tubosun wọ́n bí olúwalòní olámìídé gíwá ní oṣù kejìlá ọdún 1985 ó jẹ́ alàkóso ìlera nàìjíríà-amẹ́ríkà òun sì ni olùdásílẹ̀ lifebank tí orúkọ rẹ̀ tẹ́lẹ̀ ń jẹ́ one percent project ilé-iṣẹ́ tó wà ní nàìjíríà tó ń ṣiṣẹ́ lórí láti fi ẹ̀jẹ̀ tó dára láti ara ẹnìkan sí ẹlòmíràn ní ìlú
|
plants in space
|
peju alatise peju alatise jẹ ayàwòrán ilẹ̀ nàìjíríà akẹ́wì òǹkọ̀wé àti ọ̀kan lára àwọn òṣìṣẹ́ ni national museum of african art tí ó jẹ́ ọ̀kan lára ẹ̀yà smithsonian institution ọdún 1975 ni wọ́n bí alatise sí ìdílé mùsùlùmí òdodo ní ìlú èkó ilé-ìwé ladoke akintola university ní ìpínlẹ̀ oyo orílẹ̀-èdè nàìjíríà lẹ́yìn ìwé rẹ̀ ó ṣiṣẹ́ fún ogun ọdún ní ile-iṣẹ́ kan gẹ́gẹ́ bí ayàwòrán wọn pàtẹ àwọn àwòrán iṣẹ́ rẹ̀ nínú àtúṣe tuntun ẹlékẹtàdínlọ́gọ́ta ti venice biennale 57th edition tí àkọ́lé rẹ̀ ń jẹ́ viva arte viva kí iṣẹ́ ọnọ̀ pé kánri-kése alatise pẹ̀lú àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè nàìjìríà méjì mìíràn victor ehikhamenor àti qudus onikeku ni wọ́n jẹ́ ọmọ nàìjìríà àkọ́kọ́ ti yóò ni àǹfàní láti wà ni ìpàtẹ iṣẹ́-ọnọ̀ náá àwòrán rẹ̀ dálé ìgbé ayé ọmọ ọ̀dọ̀ obìrin alatise gba àmì-ẹ̀yẹ fnb art prize ní ọdún 2017 alatise gbé oríyìn fún ayàwòrán david dale bruce onabrakpeya nike monica davies susanna wenger nàìjìríà àti àṣà yoruba gẹ́gẹ́ bí ohun ìwúrí fún iṣẹ́ òun
|
ibidun ighodalo ibidunni ighodalo oṣù keje ọdún 1980 sí ọjọ́ kẹrìnlá ọdún 2020 jẹ́ yèyé ẹwà kan ti tẹ́lẹ̀ onímọ̀ ìṣàkóso ìṣẹ̀lẹ̀ onínúure pẹ̀lú olùṣọ àgùntàn ilé ìjọsìn trinity house ní ìlú èkó nàìjíríà ó jẹ́ olùdásílẹ̀ elizabeth r ilé-iṣé ìbátan gbogbo gbò àti ìṣẹ̀lẹ̀ pẹ̀lú ibidunni ighodalo foundation agbárí tí kìí ṣe èrè tí ó dojúkọ́ lórí àtìlẹ́yìn àwọn ìdílé pẹ̀lú ìṣòro àìrọ́mọbí ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ àti ẹbí wọ́n bí olóògbé ibidunni ighodalo ní kaduna ìpínlẹ̀ kaduna ní ọjọ́ kọ̀kàndínlógún oṣù keje ọdún 1980 ò jẹ́ ọmọ karùn-ún ti àwọn ọmọ mẹ́jọ ti olóògbé olaleye ajayi ìpìlẹ̀ ẹ̀kọ́ ibidunni lọ sí ilé-ìwé k-kotun fún tó wà ní surulere ní ìlú èkó ó sì kọ́ ẹ̀kọ́ gírámà ní federal government girls college ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ lẹ́yìn náà ó gbàwé láti kọ́ medicine ní fásìtì ti èkó èyí tí a mọ̀ sí university of lagos akoka èyí tí ó jẹ́ àyànfẹ bàbá rẹ̀ bíbẹ́ẹ̀kọ́ ìwé gbígbà rẹ̀ dàpọ̀ mọ́ ẹlòmìíràn ó sì pinnú láti ka microbiology nígbà tí o pari òye òye rẹ̀ ó gba ìkẹ́kọ̀ọ́ síwájú síi ní ìṣàkóso ìṣòwò láti ilé-ìwé ìṣòwò tí ìpínlẹ̀ èkó ó tún jẹ́ ẹlẹ́gbẹ́ ti national institute marketing
|
stella fakiyesi stella fakiyesi ti a bi c 1971 jẹ oluyaworan ti o ṣẹda lorilẹ-ede naijiria sinima ati oluyaworan awọn iṣẹ fakiyesi ni fọtoyiya ati aworan wiwo ti jẹ ifihan ni ọpọlọpọ awọn ifihan agbaye igbesiaye wan bi fakiyesi ni naijiria o kọ ẹkọ fọtoyiya ni ile-ẹkọ giga ti ile-ẹkọ giga ti art amp design lati 1993 si 1997 lẹhin ayẹyẹ ipari ẹkọ rẹ ni ọdun 1997 fakiyesi bẹrẹ si ṣiṣẹ lori adaṣe adaṣe adashe rẹ ni toronto canada o ṣe ipilẹ ati ṣiṣẹ sof art house ibi aworan aworan ati aaye iṣẹ-iṣẹ fun awọn oluyaworan ni toronto lati 1999 si 2005
|
oloye obafemi awolowo abí olóyè obáfémi jeremáyà oyèníyì awólówò ni ojó kefà osù keta odun 1909 o si kú ni ojó kesan osù karun odun 1987 6 march 1909 9 may 1987 o jé òkan nínú àwon ògunna-gbòngbò tí o ja fún òmìnira orílé-èdè naijeriya a bíi ni ilu ìkénné-rémo ní ìpínlè ogun òun nï kna ni omo okùnrin ninu gbogbo awon omo bàbá àti iya re bi orúko baba re ni dafidi shopolu awólówò eni ti o yan isé àgbè àti isée agé gedú lááyò àti orúko iya re ni màríà efúnyelá awólówò awólówò ni eni akoko ti a mo si olórí àwon ìran yorùbá ní gbogbo àgbáyé ti a npe ni asíwájú àwon yorùbá tàbí asíwájú omo oòduà
|
peteru iii ti portugal peteru iii lisbon 1717 queluz 1786 ti a pe ni capacidónio sacristão ati edificador jẹ ọba consort ti portugal ati algarves lati ọdun 1777 titi di iku rẹ o jẹ ọmọ ọba joan v ati iyawo rẹ archduchess maria ana ti austria nitorina o jẹ aburo ti ọba josefu i ati aburo maria d peteru ko kopa ninu iṣelu ati nigbagbogbo fi awọn ọran ijọba silẹ fun iyawo rẹ
|
akojo awon akorin naijiria none eyi je akojo awon akorin naijiria
|
2face innocent ujah idibia ti wo bi 18 osu kesan odun 1975 ti a mo si 2baba je akorin naijiria
|
ana mena rojas ana mena ojoibi 25 february 1997 estepona spéìn je olorin omo ile spéìn
|
amina j mohammed amina jane mohammed tí a bí ní 27 june 1971 jé olósèlú omo orílè-èdè nàìjíríà àti orílè-èdè britain òun ígbákejì akowe fun igbimọ gbogboogbo ti orilẹ-ede agbayeunited nations lowolowo laarin odun 2015 sí 2016 òun ni lo jé minisita nàìjíríà fun ètó adugbo ìpìlè àti èkó rè a bí amina jane mohammed ni ojo june 27 1961 ní ìlú liverpool england ní orílè-èdè united kingdom baba rè jé hausa-fulani òsì jé dókítá alabare àwon eranko ìyá rè sì jé noosi omo orílè-èdè united kingdom amina ni omo àkókó larin omo marun mohammed lo ilé-ìwé primari ní ìpínlè kaduna o sì tèsíwájú ní ilé-ìwé buchan ní orílè-èdè isle of man fún ìwé sekondori rè o tún tèsíwájú ní henley management college ni odún 1989 léyìn tí o parí èkó rè bàbá rè so pé kí o padà sí nàìjíríà isé rè larin 1981 sí 1991 mohammed sísé pèlú ilé-isé archon nigeria ilé-isé tí oun yaworan ilé ni odun 1991 mohammed dá ilé-isé afri-projects consortium kalè larin odun 1991 sí odun 2001 oun ni adari àti apase ilé-isé náà
|
do fagunwa
|
fifi ejindu nigerian architect ọmọọbabìnrin fifi ekanem ejindu jẹ́ ayàwòrán-ilé oníṣòwò obìnrin àti onínúure ará ilẹ̀ nàìjíríà a bí i ní ìlú ìbàdàn ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ó jẹ́ ọmọ ọmọbìnrin ọba james ekpo bassey ti ìlú cobham ní calabar ní orílẹ̀-èdè nàìjíríà ìtàn ìgbésí-ayé fifi jẹ́ ọmọ ọmọọmọ james ekpo bassey efik ọba ti ìjọba amúnisìn tí ìjókòó rẹ̀ wà ní ìlú cobham calabar nigeria ọba bassey bàbá àgbà ìyá rẹ̀ jẹ ọba ìlú cobham nípasẹ̀ àwọn aṣojú queen victoria ní 1893 gẹ́gẹ́ bí i àbájáde àjogúnbá yìí ọmọọbabìnrin fifi ń lo orúkọ ti hh obonganwan ọba james ní àwùjọ wọ́n bí ọmọọbabìnrin náà ní offiong ekanem ejindu ní ìbàdàn olú ìlú ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ nàìjíríà wọ́n tún tọ́ ọ níbẹ̀ bàbá rẹ̀ ọ̀jọ̀gbọ́n sylvester joseph una kàwé ní trinity college ní dublin àti brown university ní united states òun ni mínísítà ìlera àkọ́kọ́ ní former eastern region of nigeria ti nàìjíríà àti ọ̀kan lára national parliament ṣáájú òmìnira ó tún ṣe iṣẹ́ akadá ó sì di ọ̀kan lára àwọn olùkọ́ ilẹ̀ wa ní yunifásítì ti ìbàdàn ìyá ọmọọbabìnrin fifi the obonganwan ekpa una náà kàwé ní england ọmọọbabìnrin fifi lọ unc charlotte fifi wá lọ kẹ́kọ̀ọ́ ayàwòrán-ilé ní pratt institute ilé-ẹ̀kọ́ ayàwòrán aládàáni ní brooklyn new york ní 1983 ó kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní ó sì di obìnrin dúdú áfíríkà àkọ́kọ́ tí wọ́n fún ní barch láti ilé-ẹ̀kọ́ náà lẹ́yìn ìkẹ́kọ̀ọ́jáde fifi ṣe àwọn kọ́ọ̀sì ní massachusetts institute of technology kí ó tó lọ ṣiṣẹ́ ní ilé-iṣẹ́ aládàáni ní new york city fifi tún wá padà sí pratt institute láti gba masters nínú urban planning lẹ́yìn èyí tí ó padà sí nàìjíríà bí ó ṣe dé nàìjíríà ejindu bẹ̀rẹ̀ starcrest group of companies ilé-iṣẹ́ náà bẹ̀rẹ̀ ní 1995 ó sì jẹ́ àkójọ starcrest investment ltd starcrest associates ltd àti starcrest industries ltd gbogbo àwọn wọ̀nyí tí ń kópa nínú ilẹ̀ àti ilé epo rọ̀bì àti gáàsì àti ilé kíkọ́ ní 2013 wọ́n fún un ní àmì-ẹ̀yẹ african achievers african arts and fashion lifetime achievement award
|
ibukun oluwa abiodun awosika ìbùkúnolúwa abíọ́dún awóṣìkà bílíkísù abíọ́dún motúnráyọ̀ ọmọ́bọ́láńlé adékọ́lá tí wọ́n bí ní 24 oṣù kọkànlá 1962 jẹ́ obìnrin oníṣòwò nàìjíríà abáni-sọ̀rọ̀-ìyànjú àti òǹkọ̀wé ó jẹ́ alága tẹ́lẹ̀rí first bank of nigeria ìbẹ̀rẹ̀ ìgbésí-ayé àti ẹ̀kọ́ wọ́n bí i gẹ́gẹ́ bí i ọmọ kẹta nínú ọmọ méje ní ìbàdàn olú-ìlú ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ ibukun parí ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti ẹ̀kọ́ gíga ní st paul's african church primary school èkó àti methodist girls' high school yábàá láfarabara kí ó tó tẹ̀síwájú sí yunifásítì ifẹ̀tí a mọ̀ ní báyìí sí yunifásítì obafemi awolowo níbi tí ó ti kẹ́kọ̀ọ́ jáde pẹ̀lú bsc nínú chemistry bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé architecture ni ó ti fẹ́ kọ́kọ́ kẹ́kọ̀ọ́ nípa rẹ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ ó sì tún ṣe àwọn kọ́ọ̀sì tí ó yàn nínú accounting ó ní àwọn ìwé ẹ̀rí post graduate àti mba lẹ́yìn tí ó parí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ẹ̀kọ́ ìdókòwò ní lagos business school àti iese business school university of navarra iṣẹ́ nígbà tí ó ń ṣe ó-pọn-dandan ọdún-kan national youth service corps ìsìnlú nysc ní ìpínlẹ̀ kano ìbùkún awóṣìkà ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí i akọ́ṣẹ́ audit ní akintola williams co tí ó padà di deloitte ṣùgbọ́n padà sílé lẹ́yìn ìsìnlú náà ó sì dára pọ̀ mọ́ alibert nigeria ltd ilé-iṣẹ́ furniture gẹ́gẹ́ bí i aṣàkóso yàrá-ìfihàn nínú ìlépa rẹ̀ láti dá dúró ó dá ilé-iṣẹ́ tí í ṣẹ̀dá furniture tí ó pè ní quebees limited ní 1989 kí ó tó yí padà sí the chair centre limited àti sokoa chair centre limited lẹ́yìn náà lẹ́yìn àpapọ̀ ìdókòwò pẹ̀lú sokoa sa àti guaranty trust bank in 2004 ó jẹ́ ọ̀kan lára african leadership initiative àti aspen global leadership network ibukun awosika jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ nigerian economic summit group ọ̀kan lára àjọ nigerian sovereign wealth fund àti alága tẹ́lẹ̀rí àjọ olùtọ́jú ohun ìní women in management business and public service ní 2011 ó pẹ̀lú ẹlòmíràn dá afterschool graduate development centre ibi iṣẹ́ tí wọ́n dá sílẹ̀ láti bójútó iye àìríṣẹ́ṣe tí ó ga ní nàìjíríà ní oṣù kẹsàn-án 2015 ibukun di obìnrin àkókọ́ tí wọ́n máa yàn gẹ́gẹ́ bí i alága first bank of nigeria lẹ́yìn ìkọ̀wéfiṣẹ́lẹ̀ ọmọọba prince ajibola afonja ibukun awosika jẹ́ ọ̀kan lára iese's international advisory board iab ó tún ń jókòó lórí àjọ digital jewel limited àti cadbury nig plc òkìkí ẹ̀rọ amóhùn-máwòrán ní 2008 ibukun awosika jẹ́ ọ̀kan lára àwọn olókòwò nàìjíríà tí wọ́n farahàn nínú ẹ̀dà dragon's den áfíríkà àkọ́kọ́ ó tún máa ń ṣe olùgbàlejò ètò orí ẹ̀rọ amóhùn-máwòrán tí wọ́n pè ní business his way ó tún ṣeré nínú citation 2020 pẹ̀lútemi otedola tí kunle afolayan gbé jáde ayé rẹ̀ ibukun awosika fẹ́ abiodun awosika ẹni tí òun pẹ̀lú rẹ̀ ní ọmọ mẹ́ta
|
asake ahmed ololade tí wọ́n bí ni ojó kankànlá oṣú kẹfà ọdún 1995 tí orúkọ ìnágìjẹ rẹ̀ ǹjè asake jẹ́ olórin afrobeats láti orílẹ́ èdè nàìjíríà ójẹ́ olórin lábẹ́ àkóso ybnl nation iṣẹ́ asake kẹ́kọ̀ọ́ theatre performing arts ní obafemi awolowo university ile-ife osun state iṣẹ orin rẹ di gbajumọ ni ọdun 2020 nigbati o se àgbéjáde ere ọfẹ kan ti akole rẹ̀ jẹ́ 'mr money'
|
olaoluwa abagun nigerian lawyer and women's rights activistolaoluwa abagun jẹ́ agbẹjọ́rò nàìjíríà àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ obìnrin ìbẹ̀rẹ̀ ìgbésí-ayé àti ẹ̀kọ́ wọ́n bí abagun ní èkó ó kẹ́kọ̀ọ́ jáde ní 2008 kúrò ní queens’ college lagos níbi tí ó ti gba àmì-ẹ̀yẹ “outstanding service to college life award” gẹ́gẹ́ bí igbákejì olórí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lóbìnrin ilé-ẹ̀kọ́ náà ní kété lẹ́yìn náà ó tẹ̀síwájú sí yunifásítì obafemi awolowo university níbi tí ó ti gba bachelor of laws llb degree tí ó sì ṣe master of arts degree nínú gender and development ní institute of development studies university of sussex kìrìtẹ́ẹ́nì ni wọ́n bí abagun sínú ìdílé ẹlẹ́sìn méjì bàbá rẹ̀ jẹ́ mùsùlùmí nígbà tí màmá rẹ̀ jẹ́ kìrìtẹ́ẹ́nì òun ni ọmọ obìnrin kan ṣoṣo nínú ọmọ mẹ́rin àwọn òbí rẹ̀ nígbà tí ó ń dàgbà ó ṣàlàyé ìgbà kékeré rẹ̀ pé wọ́n mú bí wọ́n ṣe mú àwọn arákùnrin rẹ̀ bí àwọn òbí rẹ̀ ti mú u pẹ̀lú ìkọbi-ara kékeré sí akọ-ń-bábo nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò mìíràn ó fi hàn pé àwọn òbí rẹ̀ láìmọ̀ fi ẹsẹ rẹ̀ sí ojú ọ̀nà ìṣègbèfábo ó tọpasẹ̀ ìfẹ́ rẹ̀ fún ìjàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọ ènìyàn sí ọ̀rọ̀ lórí níní òye child rights act nígbà tí ó wà ní 13 ní 15 ó pàdé pẹ̀lú gómìnà nígbà náà babatunde fashola àti ìgbìmọ̀ rẹ̀ wọ́n sì fi ẹ̀rọ kọ̀m̀pútà mọyì rẹ̀ abagun ṣàpèjúwe ìṣẹ̀lẹ̀ yìí gẹ́gẹ́ bí i ara ìwúrí fún ìpinnu rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ alágbàwí fún àwọn obìnrin ìjàfẹ́tọ̀ọ́ kí ó tó kẹ́kọ̀ọ́ jáde pẹ̀lú pẹ̀lú dìgíìrì law ní 2015 abagun kọ àwọn ìwé tí ó dá lé ọ̀rọ̀ àwọn obìnrin ó sì jẹ́ lára àwọn tí ó wà ní ẹsẹ̀ tó kẹ́yìn 2014 ní ìdíje àròkọ àyájọ̀ ọ̀dọ́ áfíríkà fún iṣẹ́ rẹ̀ tí ó pè ní policies on the empowerment of young women in africa the missing piece in the african jigsaw ó tún dá girl pride circle sílẹ̀ ẹgbẹ́ tí ó ń jà fún ẹ̀tọ́ àwọn obìnrin ní nàìjíríà ní oṣù kẹta 2016 ní un commission lórí ipò àwọn obìnrin ìfágbára wọ àwọn ọmọbìnrin ó ṣe ìfilọ́lẹ̀ safe kicks initiative adolescent girls against sexual violence tí ó ń sapá láti kọ́ àwọn afarapa ìwà ipá ìbálòpọ̀ àti àwọn obìnrin lápapọ̀ lórí bí wọ́n ṣe lè dáàbò bo ara wọn nípa kíkọ́ martial arts ní oṣù kejè 2016 wọ́n ròyìn pé ó ti ń kọ́ ó lé ní ọ̀dọ́mọdébìnrin 250 láti ara ètò yìí ó tún di ará nàìjíríà kan ṣoṣo tí wọ́n fún ní owó ìgbọ̀wọ́ láti women deliver organization ó tún sọ̀rọ̀ ní eto 72 ti united nations general assembly pẹ̀lú ọ̀rọ̀ lórí ọ̀rọ̀ akọ-ń-bábo ní oṣù kejè 2017 wọ́n yàn án gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan lára àwọn ọmọ nàìjíríà tí ó tayọ láti sọ̀rọ̀ lórí àkọ́lé fast forward preparing the world to come with members of uk parliament ó mú wá sí àkíyèsí pé òun yóò sa ipá láti rí i dájú pé ìbádọ́gba takọtabo wà àti ìdàgbàsókè nínú ìkọbi-ara àwọn obìnrin nàìjíríà sí ìṣèlú nípa ṣíṣe àgbàwí fún àlàáfíà tí ó dára sí i ẹ̀kọ́ àti èròǹgbà ìjọba lórí ìṣègbèfábo ó ṣàpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí i ríridájú pé gbogbo ènìyàn àti akọ àti abo lẹ́tọ̀ọ́ sí ààyè tí ó tó láti ṣàwárí agbára wọn ní kíkún nígbà tí ó ń ṣe ìtẹnumọ́ ọ̀rọ̀ chimamanda ngozi adichie pé gbogbo wa pátá ni kí a jẹ́ aṣègbèfábo ó tún sọ pé kí a má rí ènìyàn pẹ̀lú ìtẹnumọ́ akọ tàbí abo ní ọkàn ó ṣàlàyé ìṣègbèfábo gẹ́gẹ́ bí i àbá tí ó mú ìbáṣepọ̀ àwùjọ àti ọrọ̀-ajé ọgbọọgba fún mùtúmùwà gẹ́gẹ́ bí olúborí láìfì ti takọtabo ṣe pẹ̀lú àkíyèsí pé kì í ṣe ogun takọtabo gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀ ṣe ń ṣì í gbọ́ ní oṣù kìíní 2018 ó sọ̀rọ̀ lórí bí àìnífẹ̀ẹ́sí ìṣèlú àwọn obìnrin nàìjíríà ò ṣe tẹ́ ẹ lọ́rùnó sì gbà wọ́n níyànjú láti kópa nínú ìdìbò gbogboogbò nàìjíríà 2019 àwọn ìtọ́kasí nínú a ó rí ọ̀rọ̀ tójẹmọ́ '
|
uduak isong uduak isong oguamanam jẹ́ akọ̀tàn nàìjíríà nollywood aṣàgbéjáde àti oníṣòwò tí ó ń gbé ní èkó nàìjíríà ó gbajúmọ̀ fún àwọn fíìmù adẹ́rìn-ín-pòṣónú okon lagos 2011 àti àtẹ̀lé rẹ̀ okon goes to school 2013 lost in london 2017 àti desperate housegirls 2015 falling fíìmù 2015 jẹ́ fíìmù isong oguamanam àkọ́kọ́ lábẹ́ ilé-iṣẹ́ aṣàgbéjáde eré tirẹ̀ closer pictures tí ó wà ní èkó nàìjíríà àwọn àmì-ẹ̀yẹ ní 2006 wọ́n fún isong oguamanam ní àmì-ẹ̀yẹ commonwealth short story prize àwọn fíìmù okon lagos 2011 okon goes to school 2013 kokomma 2012 lost in london 2017 kiss and tell 2011 desperate house girls 2015 fine girl 2016 it’s about your husband 2016 american boy 2017 falling film 2015 a piece of flesh 2007 holding hope 2010 stellar 2015 unfinished business 2007 edikan 2009 through the fire entanglement 2009 timeless passion 2011 bursting out 2010 troubled waters 2017 i’ll take my chances 2011 weekend getaway 2012 beyond disability 2015 champagne 2015 dining with a long spoon 2014 on bended knees 2013 stolen tomorrow 2013 mrs somebody 2012 forgetting june 2012 all that glitters 2013 misplaced 2013 lonely hearts 2013 getting over him 2018 apaye 2014 the department 2015
|
roseline òṣípìtàn yeye oba ti ìlú itori kingdom oloorì roseline omolará osípìtàn jẹ́ ọmọọba ilé yorùbá ó sí tún jẹ́ oníṣòwò orílé èdè nàìjíríà ọ tí jẹ ààrẹ àti aláàga rí fún ilé iṣé independent petroleum marketers association ti egbé àwọn obìnrin ó sí jẹ́ olùdásílẹ̀ ilé iṣé royal oil and gas òun náà sini yèyé ọba fún ìlú ìtòrì ìtàn ìgbé ayé oloorì roseline osípìtàn jẹ́ ọmọ bíbí ìpínlẹ̀ òndó ní orílé èdè nàìjíríà osípìtàn sí ń ṣíṣe gẹ́gẹ́ bí oníṣòwò àgbà fún ilé iṣé epo-rọ̀bì kàn ní orílé èdè nàìjíríà níbi tí ó tí jẹ́ ọkan lára àwọn obìnrin adarí osípìtàn ṣíṣe gẹ́gẹ́ bí ààrẹ àti aláàga fún ipman tí egbé àwọn obìnrin èyí tí o dá gẹ́gẹ́ bí òdì kejì fún egbe ipman tí orílé èdè nàìjíríà ospitian jẹ́ ẹni tí ó dá ilé iṣé first royal oil and gas sileó sí jẹ́ àyà fún ọmọoba bọ́lá osípìtàn àti yèyé ọba tí ìlú ìtòrì
|
ọlájùmọ̀kẹ́ adénọ́wọ̀
|
yewande omotoso
|
abísòyè àjàyí akínfọlárìn
|
ẹfúnṣetán aníwúrà
|
bọ́láńlé nínálowó
|
bọ́láńlé awẹ́
|
kẹ́hìndé ọlọ́runyọmí
|
àlàbá lawson
|
àlàbà jonathan
|
àbíbátù mọ́gàjí
|
dúpẹ́ jáyésinmi
|
tósìn jẹ́gẹ́dẹ́
|
rafael orozco maestre rafael josé orozco maestre march 24 1954 june 11 1992 jẹ́ olórin ara kòlómbìà o jẹ ọkan ninu awọn aṣoju ti o dara julọ ti orin colombian ati pẹlu israeli romero o ṣẹda ẹgbẹ orin el binomio de oro de américa
|
université paris-sud yunifásítì ìlú paris-sud tabi yunifasiti paris-sud jẹ ile-ẹkọ giga faranse ti a ṣẹda ni oṣu kini ọjọ 1 ọdun 1971 o parẹ ni oṣu kini ọjọ 1 ọdun 2020 ni ojurere ti yunifásítì ìlú paris-saclay ti o tẹle atẹjade ni iwe akọọlẹ iṣeduro ti aṣẹ ti o ṣẹda ile-ẹkọ giga tuntun ni oṣu kọkanla ọjọ 5 ọdun 2019
|
sean lock sean lock 22 kẹrin 1963 - 16 oṣu kẹjọ 2021 jẹ apanilẹrin ati oṣere gẹẹsi kan o bẹrẹ iṣẹ awada rẹ gẹgẹbi apanilẹrin imurasilẹ ati ni ọdun 2000 o gba aami eye awada ilu gẹẹsi ni ẹka apanilẹrin live ti o dara julọ ati pe o tun yan fun aami eye perrier comedy o jẹ olori ẹgbẹ lori ifihan nronu awada ikanni 4 8 ninu awọn ologbo 10 lati ọdun 2005 si 2015 ati 8 ninu 10 awọn ologbo ṣe kika lati ọdun 2012 titi o fi ku ni ọdun 2021 locke ti farahan ni ọpọlọpọ igba lori ipele lori tẹlifisiọnu ati lori redio awọn isunmọ rẹ nigbagbogbo jẹ lori-oke ati jiṣẹ ni aṣa ti o ku o tun kowe fun bill bailey lee evans ati mark lamarr titiipa ni a dibo fun apanilerin imurasilẹ 55th ti o tobi julọ ni ikanni 4's 100 stand-ups greatest ni 2007 ati pe o wa ni ipo 19th ninu atokọ 2010 ti a tunwo o ti jẹ alejo deede lori awọn ifihan nronu miiran pẹlu bbc's have i get news for you qi ati pe wọn ro pe o ti pari tete aye lock ni a bi ni chertsey surrey ni ọjọ 22 oṣu kẹrin ọdun 1963 baba rẹ ni sidney lock ẹniti o ṣiṣẹ ni ile-iṣẹ ikole iya rẹ si ni mary ọmọe mccreesh ti idile rẹ wa lati cullaville county armagh lock abikẹhin ti awọn ọmọde mẹrin dagba ni woking surrey nibiti o ti lọ si ile-iwe st john baptisti lakoko awọn ọdun ọdọmọkunrin lock o wo awọn fiimu ile aworan lori bbc meji o si darukọ andrei tarkovsky's 1979 fiimu itan-akọọlẹ imọ-jinlẹ stalker bi ipa nla julọ rẹ ni ọdun 1981 o fi eto-ẹkọ silẹ pẹlu ipele e ni ipele a-gẹẹsi lẹ́yìn náà bàbá rẹ̀ fún un ní iṣẹ́ tó ń bọ́ àwọn pákó kọ́ǹkà látinú ilé lẹhin lilo ọdun meje bi oṣiṣẹ o lọ o mu awọn iṣẹ lọpọlọpọ fún ọ̀sẹ̀ mẹ́fà ó ṣiṣẹ́ ní oko kan ní ilẹ̀ faransé gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́ ewúrẹ́ ó sì ṣiṣẹ́ ní kibbutz ní ísírẹ́lì lakoko yii o tun ṣiṣẹ bi olutọju ile-igbọnsẹ ati oṣiṣẹ ọfiisi fun ẹka ilera ati aabo awujọ lakoko iṣẹ rẹ bi oṣiṣẹ o ni idagbasoke akàn ara lẹ́yìn náà ló pinnu láti máa ṣe eré ó sì forúkọ sílẹ̀ sí drama center london bó tilẹ̀ jẹ́ pé kò pẹ́ tó fi rí i pé òun ti ṣe àṣìṣe ó jáwọ́ ó sì padà di òṣìṣẹ́ lẹhin lock rii awọn apanilẹrin bii alexei sayle ati paul merton ṣe ni awọn ẹgbẹ awada o pinnu lati lepa awada ni gbogbo igba naa o ṣabẹwo awọn ifihan awada ni awọn ile-ọti ilu lọndọnu o bẹrẹ si ṣe awọn mics ṣiṣi bi ifisere ni ọdun 1988 lock ni gig osise akọkọ rẹ ni ile-ọti kan ni stoke newington lọndọnu lẹhin ti o san 15 fun awọn iṣẹju 20 rẹ o rii pe o le lepa awada bi iṣẹ ṣiṣẹ iṣẹ tẹlifisiọnu kutukutu lock pẹlu ipa atilẹyin lẹgbẹẹ rob newman ati david baddiel ninu jara 1993 newman ati baddiel ninu awọn nkan eyiti o pẹlu irin-ajo pẹlu wọn gẹgẹbi iṣe atilẹyin wọn frank skinner ati eddie izzard ni a ka bi awọn ipa pataki lori awada rẹ igbagbọ olokiki ni pe lock jẹ apanilẹrin akọkọ lati ṣe ni wembley arena nitori pe o jẹ iṣe atilẹyin fun newman ati baddiel ṣugbọn lakoko ti lock jẹ iṣe atilẹyin o han nikan ni awọn skits ni aarin iṣafihan naa awọn iṣẹju 15 ti ibanujẹ ati awọn ile itaja giga 15 bọtini han nigbagbogbo lori ọpọlọpọ awọn ifihan nronu redio ati pe a kọ ni bill bailey's 1998 bbc2 jara njẹ bill bailey ni ni oṣu kejila ọdun 1998 o ṣafihan ifihan tirẹ lori bbc radio 4 awọn iṣẹju 15 ti ibanujẹ lakoko bi awaoko-iṣẹlẹ marun ifihan naa tun ṣe afihan awọn oṣere kevin eldon ati hattie hayridge ile-iṣẹ naa jẹ titiipa eavesdropping lori awọn aladugbo rẹ lori afara guusu london rẹ gbogbo rẹ nipasẹ lock eldon ati hayridge ni lilo ohun elo bugging ti a fi sori ẹrọ nipasẹ olupilẹṣẹ rẹ “hot bob” eldon ti a mọ si “the bugger king” tun “ ko ni nkankan lati ṣe pẹlu ẹran tabi ibalopo awọn iṣẹju 15 ti ibanujẹ ran fun jara kan ti awọn iṣẹlẹ mẹfa ni ipari 1998 ati ibẹrẹ 1999 ni ọdun 1999 awọn iṣẹju 15 ti ibanujẹ ti gbooro si jara idaji-wakati 15 storeys high àjọ-kọ nipasẹ lock ati martin trenaman lati ile-iṣọ ile-iṣọ kanna ihuwasi lock ni bayi fun ẹlẹgbẹ yara kan errol ti o lewu ati iṣẹ kan ni adagun odo agbegbe bakanna bi iwulo ati aibikita kan a ko lo ẹrọ bugging mọ ṣugbọn awọn antics ti awọn aladugbo lock tun jẹ ẹya pataki ninu iṣafihan naa awọn iṣẹlẹ ti jara yii jẹ lẹsẹsẹ pupọ ni aṣa sitcom “deede” botilẹjẹpe wọn tun ṣafihan ami iyasọtọ lock ti dudu arin takiti ere 15 storeys high yoo gbe lọ si tẹlifisiọnu lẹhin jara redio meji pẹlu ihuwasi lock ti a fun lorukọmii 'vince' fun jara ọkan-pipa meji ni 2002 ati 2004 ni akọkọ ti a gbejade lori aṣayan bbc o tẹle vince ti ko ni ihalẹ ati alabaṣiṣẹpọ aṣiwere rẹ errol benedict wong o ṣe ifamọra ẹgbẹ kan ti o tẹle lẹhin itusilẹ rẹ bi ṣeto apoti vhs ati dvd
|
université paris-diderot yunifásítì ìlú paris-diderot tabi yunifasiti paris-diderot jẹ ile-ẹkọ giga faranse ti a ṣẹda ni oṣu kini ọjọ 1 ọdun 1971 o parẹ ni oṣu kini ọjọ 1 ọdun 2020 ni ojurere ti université paris cité ti o tẹle atẹjade ni iwe akọọlẹ iṣeduro ti aṣẹ ti o ṣẹda ile-ẹkọ giga tuntun ni oṣu kẹta ọjọ 20 ọdun 2019
|
akínwùnmí ambọ̀dé
|
feminism
|
ìṣègbèfábo
|
ìjà fẹ́tọ̀ọ́ obìnrin ìṣègbèfábo feminism
|
eka soup eka soup eka soup tí a tún mọ̀ sí ekuku jẹ́ oúnjẹ ẹ̀yà méta ní apá ìla-oòrùn ilè nàìjíríà èkùrọ́ ẹ̀pà sísun àti kóró benne tí a gún ni a fi máa ń se eka soup fufu ni ó dùn jù láti fi jẹ́ orísun ọbẹ̀ náà wọ́pọ̀ láàrín àwọn èèyàn benue kogi àti cross river ohun èlò benne sísun ẹ̀pà sísun èkùrọ́ ẹran ẹ̀fọ́ ewúro maggi àlùbọ́sà ìsebè àti edé ṣíṣe láti se ọbẹ̀ eka a gbọ́dọ̀ kọ́kọ́ dín ẹran fún ìṣẹ́jú díẹ̀ lẹ́yìn náà a máa sun kóró benne àti ẹ̀pà súnsun àti èkùrọ́ a sì máa lọ́ ọ́ pọ̀ ohun tí a gún pọ̀ yìí ni a máa wá dì nídì kékèèké tí a sì máa sè nínú epo ewúro àti ohun èlò mìíràn bíi maggi àlùbọ́sà iyọ̀ edé àti bẹ́ẹ̀ bẹ́è lọ ọbẹ̀ tó jọ ẹka àwọn ọbè mìíràn tí a fi ẹ̀pà àti kóró ṣe ni oúnjẹ mìíràn òkèlè tí a lè fi jẹ ọbẹ̀ eka ni eba iyán àti fùfú
|
gizdodo gizdodo jẹ́ oúnjẹ̀ tí a fi iwe adìyẹ àti dòdò se ó jẹ́ oúnjẹ àfikún tí a máa ń jẹ ní ilé àti òde ìsọníṣókí àsepọ̀ yìí ni a sè nípa lílo dòdò iwe adìyẹ èròjà ìsebẹ̀ lóríṣiríṣi àlùbọ́sà tàtàṣé àti rodo wọ́n tún máa ń fi káròtù si dòdò àti iwe adìyẹ yẹn ni a máa kọ́kọ́ dín lọ́tọ̀ọ̀tọ̀ lẹ́yìn náà a máa wá da méjèèjì pọ̀ sínu ata ọbè tí a sè pẹ̀lú àwọn èròjà tókù bíi àlùbọ́sà ata maggi iyọ̀ àti bẹ́ẹ̀ bẹ́è lọ a lè jẹ gizdodo lásán a sì lè je é pẹ̀lú ìrẹsì tàbí spaghetti
|
adalu àdàlú jẹ́ oúnjẹ ìbílẹ̀ orílẹ̀-èdè nàìjíríà tí o gbajúmò láàrín ẹ̀yà yorùbá àwọn igbó náà tún maa ń jẹ ẹ́ gẹ́gẹ́ bí óúnjẹ tàbí ìpanu oúnjẹ náà jẹ́ èyí tí a ṣe láti ara àgbàdo àti ẹ̀wà àdàlú jẹ́ óúnjẹ́ afúnilókún ati oúnjẹ amaradagba jẹ aládùn alailẹgbẹ ìlànà àgbàdo jẹ ọkan nínú àwọn èròjà pàtàkì fun ounjẹ yii àgbàdo ati ẹwà jẹ gbogbo ohun ti o nilo lẹhinna ṣe ounjẹ awọn eroja miiran bii epo ọpẹ alubosa ata ati iyo ni a fi kun lati fun ounjẹ naa ni itọwo alailẹgbẹ dodo tàbí ẹja le ṣee lo lati jẹ ounjẹ yii
|
nkwobi spicy cow feet jẹ́ oúnjẹ aládùn tó wọ́pọ́ ní àwọn ilé ounjẹ tí a tún mọ̀ sí nkwobi irú oúnjẹ yìí wọ́pọ̀ láàrin àwọn ẹ̀yà igbo ó jẹ́ ọbẹ̀ tí a fi òpó ẹ̀sẹ̀ ẹran màlúù sè àwọn èròjà tí a fi n pèsè rẹ̀ àwọn èròjà tí a ní lò láti fi se ohun ìpanu àwọn ni epo pupa kaun èròjà nọ́tmẹẹ̀gì ewé utazi ata alùbọ́sà àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ ọ̀nà míràn tí a lè potash ni ngu a lè lo ewé lespinach dípò utazia tí kò bá sí ní tòsí a sábà máa ń se nkwobi ní ilé bí ó tilẹ̀ jẹ́ wípé ó wọ́pọ̀ ní ilé àwọn oloúnjẹ ọbẹ̀ náà wáyé látara ẹsẹ ẹran màlúù tí a ti bọ̀ pẹ̀lú alùbọ́sà àti àwọn oríṣiríṣi èròjà edé calabash nutmeg àti ata lílọ̀ ní a ma fi kun lẹ́yìn ẹ̀ ẹ̀sẹ̀ màlúù tí a ti bọ̀ náà ní a ó pòpọ̀ mọ́ òróró sì rọra ròó kó má báà jóná
|
spicy cow feet
|
Subsets and Splits
No community queries yet
The top public SQL queries from the community will appear here once available.